Publicidade

Atos 20

Paulu kọjá Makedonia àti Giriki

1 Nígbà ariwo náà rọlẹ̀, Paulu ránṣẹ́ pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn, ó gbà wọ́n ìyànjú, ó dágbére fún wọn, ó dìde láti lọ Makedonia. 2 Nígbà ó la apá ìhà wọ̀nyí kọjá, ó ti fi ̀rọ̀ púpọ̀ gbà wọ́n ìyànjú, ó ilẹ̀ Giriki. 3 Ó dúró níbẹ̀ oṣù mẹ́ta, nígbà àwọn Júù dènà é, ó ti ń pète àti ọkọ̀ ojú omi lọ Siria, ó pinnu rẹ̀ láti gbà Makedonia padà lọ. 4 Sopateru ará Berea ọmọ Pirusi a lọ Asia, àti nínú àwọn ará Tẹsalonika, Aristarku àti Sekundu, àti Gaiusi ará Dabe, àti Timotiu; Tikiku àti Tirofimu ará Asia.

A Eutiku dìde nínú òkú Troasi

5 Ṣùgbọ́n àwọn wọ̀nyí lọ síwájú, wọ́n dúró ni Troasi. 6 Àwa ṣíkọ̀ láti Filipi lọ lẹ́yìn àjọ àìwúkàrà, a ̀dọ̀ wọn Troasi ni ọjọ́ méje.

7 Ọjọ́ èkínní ̀sẹ̀ nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn péjọ láti bu àkàrà, Paulu wàásù fún wọn, ó múra láti lọ ọjọ́ kejì: ó fa ̀rọ̀ rẹ̀ gùn títí di àárín ̀gànjọ́. 8 Fìtílà púpọ̀ iyàrá òkè náà, níbi wọn gbé péjọ . 9 ̀dọ́mọkùnrin kan a ń Eutiku jókòó lójú fèrèsé, oorun wọ̀ ́ lára; Paulu ti pẹ́ ìwàásù, ó ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n lójú oorun, ó ṣubú láti òkè kẹta sílẹ̀, a gbé e dìde òkú. 10 Nígbà Paulu sọ̀kalẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ i, ó gbé e mọ́ra, ó , "ṣe yọ ara yín lẹ́nu; nítorí òun láààyè." 11 Nígbà ó tún gòkè lọ, ó jẹ oúnjẹ Olúwa, ó sọ̀rọ̀ pẹ́ títí ó fi di àfẹ̀mọ́júmọ́, nígbà náà ni ó lọ. 12 Wọ́n ọmọkùnrin náà lọ sílẹ̀ láààyè, inú gbogbo wọn dùn lọ́pọ̀lọ́pọ̀.

Ìdágbére Paulu àwọn Alàgbà Efesu

13 Nígbà ti àwa ṣáájú, àwa ṣíkọ̀ lọ Asosi, níbẹ̀ ni a ti lérò láti gba Paulu sínú ọkọ̀: nítorí bẹ́̀ ni ó pinnu rẹ̀, òun tìkára rẹ̀ ń fẹ́ ti ̀nà-ẹsẹ̀ lọ. 14 Nígbà ó pàdé wa Asosi, a gbà á sínú ọkọ̀, a Miletu. 15 Nígbà a ṣíkọ̀ kúrò níbẹ̀, ọjọ́ kejì a ̀kánkán Kiosi; ọjọ́ kejì rẹ̀ a Samosi, ni ọjọ́ kejì rẹ̀ a Miletu. 16 Paulu ṣa ti pinnu rẹ̀ láti ọkọ̀ ojú omi kọjá Efesu, nítorí ki ó ba à lo àkókò kankan ni Asia: nítorí ó ń yára yóò ṣe ṣe é ṣe fún un láti Jerusalẹmu lọ́jọ́ Pentikosti.

17 àti Miletu ni Paulu ti ránṣẹ́ Efesu, láti àwọn alàgbà ìjọ sọ́dọ̀ rẹ̀. 18 Nígbà wọ́n ̀dọ̀ rẹ̀, ó fún wọn , "̀yin tìkára yín mọ̀, láti ọjọ́ kìn-ín-ní mo Asia, mo ti yín gbé, gbogbo àkókò náà. 19 mo ti ń fi ìrẹ̀lẹ̀ inú gbogbo sin Olúwa, àti omijé púpọ̀, pẹ̀ìdánwò, ó mi, nípa rìkíṣí àwọn Júù. 20 èmí ti fàsẹ́yìn láti sọ ohunkóhun ó ṣàǹfààní fún un yín, àti láti máa kọ́ yín gbangba àti láti ilé ilé. 21 mo ń sọ fún àwọn Júù, àti fún àwọn Giriki pẹ̀, ti ìrònúpìwàdà Ọlọ́run, àti ti ìgbàgbọ́ nínú Jesu Kristi Olúwa wa.

22 "Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ó, ̀mi ń Jerusalẹmu, láìmọ̀ ohun yóò mi níbẹ̀. 23 ṣe ̀Mímọ́ ń sọ ìlú gbogbo , ìdè àti ìyà ń bẹ fún mi. 24 Ṣùgbọ́n èmi ka ọkàn mi nǹkan rárá bi ohun ó ṣọ̀wọ́n fún mi àti iṣẹ́ ìránṣẹ́ mo gbà lọ́dọ̀ Jesu Olúwa, láti máa ròyìn ìyìnrere oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run.

25 "Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ó, èmi mọ̀ gbogbo yín, láàrín ẹni èmi ń wàásù ìjọba Ọlọ́run, yóò ojú mi mọ́. 26 Nítorí náà mo yín ṣe ẹlẹ́rìí lónìí yìí , ọrùn mi mọ́ kúrò nínú ̀jẹ̀ ènìyàn gbogbo. 27 Nítorí èmi fàsẹ́yìn láti sọ gbogbo ìpinnu Ọlọ́run fún un yin. 28 kíyèsára yin, àti gbogbo agbo ̀Mímọ́ fi yín ṣe alábojútó rẹ̀, láti máa tọ́ìjọ Ọlọ́run, ó fi ̀jẹ̀ rẹ̀ . 29 Nítorí èmi mọ̀ , lẹ́yìn lílọ mi, ìkookò búburú yóò wọ àárín yín, yóò agbo . 30 Láàrín ̀yin tìkára yín ni àwọn ènìyàn yóò dìde, wọn yóò máa sọ̀rọ̀-òdì, láti fa àwọn ọmọ-ẹ̀yìn sẹ́yìn wọn. 31 Nítorí náà máa ṣọ́ra, ki máa rántí , fún ọdún mẹ́ta, èmi dẹ́kun láti máa fi omijé kìlọ̀ fún olúkúlùkù ̀sán àti òru.

32 "Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ará, mo fi yín Ọlọ́run lọ́wọ́ àti ̀rọ̀ oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀, ó gbé yín dúró, ó fún yín ìní láàrín gbogbo àwọn a sọ di mímọ́. 33 Èmí ṣe ojúkòkòrò fàdákà, tàbí wúrà, tàbí aṣọ ẹnikẹ́ni. 34 ̀yin tìkára yín à mọ̀ , ọwọ́ mi wọ̀nyí ni mo fi ṣiṣẹ́ láti fi pèsè fún àìní mi, àti àwọn ó pẹ̀mi. 35 Nínú ohun gbogbo mo fi àpẹẹrẹ fún un yín , nípa ṣíṣe iṣẹ́ bẹ́̀, ó yẹ máa ran àwọn aláìlera lọ́wọ́, ki máa rántí ̀rọ̀ Jesu Olúwa, òun tìkára rẹ̀ , Láti fún ni ìbùkún ju láti gbà lọ."

36 Nígbà ó nǹkan wọ̀nyí, ó kúnlẹ̀, ó gbogbo wọn gbàdúrà. 37 Gbogbo wọn sọkún gidigidi, wọ́n rọ̀ mọ́ Paulu lọ́rùn, wọ́n fi ẹnu ó lẹ́nu. 38 Inú wọn bàjẹ́ jùlọ fún ̀rọ̀ ó sọ , wọn yóò ojú òun mọ́, wọ́n sìn ín títí inú ọkọ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-