Publicidade

Atos 9

Ìyípadà Saulu

1 Ṣùgbọ́n síbẹ̀, Saulu ń tẹ̀síwájú nínú mímí èémí ìhalẹ̀ mọ́ni àti ìpani àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Olúwa. Ó tọ olórí àlùfáà lọ, 2 ó béèrè ìwé lọ́wọ́ rẹ̀ Sinagọgu ń bẹ ìlú Damasku , òun ẹnikẹ́ni ń bẹ ni ̀yìí, ìbá à ṣe ọkùnrin, tàbí obìnrin, òun wọn dídè Jerusalẹmu. 3 Ó ṣe, ó ti ń lọ, ó súnmọ́ Damasku; lójijì, ìmọ́lẹ̀ láti ̀run mọ́lẹ̀ i . 4 Ó ṣubú lulẹ̀, ó gbọ́ ohùn ó ń fọ̀ i , "Saulu, Saulu, èéṣe ti ìwọ fi ń ṣe inúnibíni mi?"

5 Ó , "Ìwọ ta ni, Olúwa?"

Olúwa fún , "Èmi ni Jesu, ẹni ti ìwọ ń ṣe inúnibíni . 6 Dìde, o lọ ìlú náà, a ó sọ fún nípa ohun ìwọ yóò ṣe."

7 Àwọn ọkùnrin wọ́n ń Saulu lọ àjò dúró, wọn le sọ ohun kan, wọn gbọ́ ohùn náà ṣùgbọ́n wọn ẹnìkan. 8 Saulu dìde ilẹ̀; nígbà ojú rẹ̀ ohunkóhun; ṣùgbọ́n wọ́n á lọ́wọ́ wọ́n un Damasku. 9 Ó gbé ọjọ́ mẹ́ta ni àìríran jẹ, bẹ́̀ ni mu.

10 Ọmọ-ẹ̀yìn kan Damasku, a ń ni Anania! Olúwa fún un lójúran , "Anania!"

Ó , "ó, èmi nìyí, Olúwa."

11 Olúwa fún un , "Dìde ó lọ ilé Judasi òpópónà Tààrà, ó béèrè ẹni a ń ni Saulu, ara Tarsu, ó, ó ń gbàdúrà. 12 Òun ri ọkùnrin kan lójúran ti a ń ni Anania, ó wọlé, ó fi ọwọ́ e, ó ríran."

13 Anania dáhùn , "Olúwa mo gbúròó ọkùnrin yìí lọ́dọ̀ ̀pọ̀ ènìyàn, gbogbo búburú ti ó ṣe àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ ni Jerusalẹmu. 14 Ó gba àṣẹ láti ̀dọ̀ àwọn olórí àlùfáà ìhín yìí, láti de gbogbo àwọn ti ń pe orúkọ rẹ."

15 Ṣùgbọ́n Olúwa fún un , "Máa lọ; nítorí ohun èlò ààyò ni òun jẹ́ fún mi, láti gbé orúkọ mi lọ iwájú àwọn aláìkọlà, àti àwọn ọba, àti àwọn ọmọ Israẹli. 16 Nítorí èmi o fi gbogbo ìyà ti le ṣàìjẹ nítorí orúkọ mi hàn án."

17 Anania lọ, ó wọ ilé náà, nígbà ó fi ọwọ́ rẹ̀ Saulu, ó , "Arákùnrin Saulu, Olúwa ni ó rán mi, Jesu ó fi ara hàn lọ́ìwọ , ìwọ ba à ríran, ó kún fún ̀Mímọ́." 18 Lójúkan náà nǹkan kan ti ó dàbí ìpẹ́ bọ kúrò lójú rẹ̀, ó ríran; ó dìde, a bamitiisi rẹ̀. 19 Nígbà ó jẹun, ara rẹ̀ mókun.

Saulu Damasku àti Jerusalẹmu

Saulu pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Damasku ọjọ́ púpọ̀. 20 Lójúkan náà ó ń wàásù Kristi nínú àwọn Sinagọgu , Jesu ni Ọmọ Ọlọ́run. 21 Ẹnu gbogbo àwọn ti ó ń gbọ́, wọn , "Èyí ha kọ ẹni ti ó ti fóòro àwọn ti ń pe orúkọ yìí ni Jerusalẹmu? Nítorí èyí náà ni ó sa ṣe ìhín yìí, láti wọn dìde lọ sọ́dọ̀ àwọn olórí àlùfáà." 22 Ṣùgbọ́n Saulu ń pọ̀ i agbára ó ń dààmú àwọn Júù ó ń gbé Damasku, ó fihàn , èyí ni Kristi náà.

23 Lẹ́yìn ìgbà ọjọ́ púpọ̀ kọjá, àwọn Júù ń gbìmọ̀ láti pa á. 24 Ṣùgbọ́n ìdìtẹ̀ wọn di mọ̀ fún Saulu. Wọ́n ń ṣọ́ ẹnu ibodè pẹ̀lọ́sàn àti lóru, wọ́n ń ̀láti pa á. 25 Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ gbé òru, wọ́n sọ̀ ́ kalẹ̀ lára odi nínú agbọ̀n.

26 Nígbà ti Saulu de Jerusalẹmu ó pète láti da ara rẹ̀ pọ̀ mọ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn; gbogbo wọn bẹ̀rẹ̀, nítorí wọn gbàgbọ́ ọmọ-ẹ̀yìn kan ni. 27 Ṣùgbọ́n Barnaba un, ó sìn ín lọ sọ́dọ̀ àwọn aposteli, ó sọ fún wọn ó ti Olúwa ̀, àti ó ti fi ìgboyà wàásù Damasku orúkọ Jesu. 28 Saulu pẹ̀wọn, ó ń wọlé, ó ń jáde Jerusalẹmu. Ó ń fi ìgboyà wàásù ni orúkọ Olúwa. 29 Ó ń sọ̀rọ̀ lòdì àwọn ará Helleni, ó ń wọ́n iyàn; ṣùgbọ́n wọn ń pète láti pa a. 30 Nígbà àwọn arákùnrin mọ̀, wọ́n sọ̀kalẹ̀ lọ Kesarea, wọ́n rán an lọ Tarsu.

31 Nígbà náà ni ìjọ ni àlàáfíà yíká gbogbo Judea àti ni Galili àti ni Samaria, wọn ń fẹsẹ̀múlẹ̀, wọn ń rìn ìbẹ̀Olúwa, àti ni ìtùnú ̀Mímọ́, wọn ń pọ̀ i.

Aenea àti Dọkasi

32 Ó ṣe, Peteru ti ń kọjá lọ káàkiri láàrín wọn, ó sọ̀kalẹ̀ lọ pẹ̀si ̀dọ̀ àwọn ènìyàn mímọ́ ti ń gbé ni Lida. 33 Níbẹ̀ ni ó ọkùnrin kan ti a Aenea ó ti dùbúlẹ̀ lórí àkéte ni ọdún mẹ́jọ, ó ààrùn ̀gbà. 34 Peteru fún un , "Aenea, Jesu Kristi láradá; dìde ó tún àkéte rẹ ṣe." Ó dìde lójúkan náà. 35 Gbogbo àwọn ń gbé Lida àti Ṣaroni i, wọn yípadà Olúwa.

36 Ọmọ-ẹ̀yìn kan Joppa ti a ń ni Tabita (èyí ó túmọ̀ Dọkasi); obìnrin yìí pọ̀ ni iṣẹ́ oore, àti ìtọrẹ àánú ṣíṣe. 37 àkókò náà ni ó nínú àìsàn, ó , wọ́n wẹ òkú rẹ̀, wọ́n gbé òkú rẹ̀ iyàrá òkè. 38 Lida ti súnmọ́ Joppa, nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn gbọ́ Peteru níbẹ̀, wọ́n rán ọkùnrin méjì i láti bẹ̀ ́ , "ṣe jáfara láti ̀dọ̀ wa."

39 Peteru dìde, ó wọn lọ. Nígbà ó , wọ́n un lọ iyàrá òkè náà, gbogbo àwọn opó dúró í wọn sọkún, wọ́n ń fi ̀àti aṣọ Dọkasi hàn án, nígbà ó pẹ̀wọn.

40 Ṣùgbọ́n Peteru ti gbogbo wọn sóde, ó kúnlẹ̀, ó gbàdúrà; ó yípadà òkú, ó "Tabita, dìde." Ó la ojú rẹ̀, nígbà ó Peteru, ó dìde jókòó. 41 Ó na ọwọ́ rẹ̀ i, ó á dìde; nígbà ó pe àwọn ènìyàn mímọ́ àti àwọn opó, ó fi wọn lọ́wọ́ láààyè. 42 Èyí di mọ̀ gbogbo Joppa; ̀pọ̀lọpọ̀ gba Olúwa gbọ́. 43 Ó gbé ọjọ́ púpọ̀ ni Joppa ̀dọ̀ ọkùnrin kan Simoni oníṣọ̀nà-awọ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-