Pular para o conteúdo
Publicidade

Resultados da busca por "fé"

260 resultados encontrados

  1. Filipenses 4

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 4
    Mostrando versículos 13–23 de 23

    134.13: 2Kọ 12.9.Èmi le ṣe ohun gbogbo nínú Kristi ẹni ti ń fi agbára fún mi.

    20Ṣùgbọ́n ògo ni fún Ọlọ́run àti Baba wa láé àti láéláé. Àmín.

    23 4.23: Ga 6.18; Fm 25. Oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa wa, kí ó wà pẹ̀lú ẹ̀mí yín. Àmín.

  2. 1 Timóteo 6

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 6
    Mostrando versículos 6–21 de 21

    6Ṣùgbọ́n ìwà-bí-Ọlọ́run pẹ̀lú ìtẹ́lọ́rùn èrè ńlá ni.

    12Máa ja ìjà rere ti ìgbàgbọ́, di ìyè àìnípẹ̀kun mú nínú èyí tí a pè ọ sí, ti ìwọ sì ṣe ìjẹ́wọ́ rere níwájú ẹlẹ́rìí púpọ̀.

    21èyí tí àwọn ẹlòmíràn jẹ́wọ́ rẹ̀ tí wọ́n sì ṣìnà ìgbàgbọ́.Kí oore-ọ̀fẹ́ wà pẹ̀lú rẹ.

  3. Miquéias 1

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 1
    Mostrando versículos 3–11 de 16

    3Wò ó! Olúwa ń bọ̀ wá láti ibùgbé rẹ̀;yóò sọ̀kalẹ̀, yóò sì tẹ ibi gíga ayé mọ́lẹ̀.

    10Ẹ má ṣe sọ ní Gatiẹ má ṣe sọkún rárá.Ní ilẹ̀ Beti-Oframo yí ara mi nínú eruku.

    11Ẹ kọjá lọ ni ìhòhò àti ni ìtìjú,ìwọ tí ó ń gbé ni Ṣafiri.Àwọn tí ó ń gbé ni Saananikì yóò sì jáde wá.Beti-Eseli wà nínú ọ̀fọ̀;a ó sì gba ààbò rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ yin.

  4. Colossenses 4

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 4
    Mostrando versículos 2–12 de 18

    2Ẹ fi ara yín jì fún àdúrà gbígbà, kí ẹ ṣọ́ra kí ẹ sì máa dúpẹ́;

    4Ẹ gbàdúrà pé kí èmi le è máa kéde rẹ̀ kedere gẹ́gẹ́ bí ó ti tọ́ fún mi.

    12Epafira, ẹni tí ń ṣe ọ̀kan nínú yín àti ìránṣẹ́ Kristi Jesu kí i yín. Òun fi ìwàyáàjà gbàdúrà nígbà gbogbo fún un yín, kí ẹ̀yin kí ó lè dúró ní pípé nínú ohun gbogbo nínú ìfẹ́ Ọlọ́run.

  5. Mateus 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 8–16 de 17

    8Ẹ so èso tí ó yẹ fún ìrònúpìwàdà.

    11"Èmi fi omi bamitiisi yín fún ìrònúpìwàdà. Ṣùgbọ́n lẹ́yìn mi ẹnìkan tí ó pọ̀jù mí lọ ń bọ̀, bàtà ẹni tí èmi kò tó gbé. Òun ni yóò fi Ẹ̀mí Mímọ́ àti iná bamitiisi yín.

    16Bí ó si tí ṣe ìtẹ̀bọmi fún Jesu tán, Ó jáde láti inú omi. Ní àkókò náà ọ̀run ṣí sílẹ̀ fún un, Ó sì rí Ẹ̀mí Ọlọ́run ń sọ̀kalẹ̀ bí àdàbà, ó sì bà lé e.

  6. Jonas 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 1–5 de 10

    1Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Jona wá nígbà kejì wí pé:

    2"Dìde lọ sí Ninefe, ìlú ńlá a nì, kí o sì kéde sí i, ìkéde tí mo sọ fún ọ."

    5Àwọn ènìyàn Ninefe sì gba Ọlọ́run gbọ́. Wọ́n sì kéde àwẹ̀, gbogbo wọ́n sì wọ aṣọ ọ̀fọ̀, bẹ̀rẹ̀ láti orí ọmọdé títí dé orí àgbà wọn.

  7. Judas 1

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 1
    Mostrando versículos 2–22 de 25

    2Kí àánú, àlàáfíà àti ìfẹ́ kí ó máa jẹ́ tiyín ní ọ̀pọ̀lọpọ̀.

    20Ṣùgbọ́n ẹ̀yin, olùfẹ́, ti ẹ ń gbé ara yín ró lórí ìgbàgbọ́ yín tí ó mọ́ jùlọ, ti ẹ ń gbàdúrà nínú Ẹ̀mí Mímọ́.

    22Ẹ máa ṣàánú fún àwọn tí ń ṣe iyèméjì.

  8. Hebreus 10

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 10
    Mostrando versículos 14–19 de 39

    14Nítorí nípa ẹbọ kan a ti mú àwọn tí a sọ di mímọ́ pé títí láé.

    15Ẹ̀mí Mímọ́ sì ń jẹ́rìí fún wa pẹ̀lú, nítorí lẹ́yìn tí ó wí pé,

    19Ará, ǹjẹ́ bí a ti ní ìgboyà láti wọ inú Ibi Mímọ́ Jùlọ nípasẹ̀ ẹ̀jẹ̀ Jesu,

  9. Marcos 1

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 1
    Mostrando versículos 1–43 de 45

    1Ìbẹ̀rẹ̀ ìyìnrere nípa Jesu Kristi, Ọmọ Ọlọ́run.

    33Gbogbo ìlú si péjọ ni ẹnu-ọ̀nà.

    43Jesu sì kìlọ̀ fún un gidigidi

  10. Jó 33

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 33
    Mostrando versículos 10–29 de 33

    10Kíyèsi i, Ọlọ́run ti rí àìṣedéédéé pẹ̀lú mi;ó kà mí sì ọ̀tá rẹ̀.

    17kí ó lè fa ènìyàn sẹ́yìn kúrò nínú ètè rẹ̀;kí ó sì pa ìgbéraga mọ́ kúrò lọ́dọ̀ ènìyàn;

    29"Wò ó! Nǹkan wọ̀nyí ni Ọlọ́runmáa ń ṣe fún ènìyàn nígbà méjì àti nígbà mẹ́ta,

  11. Lamentações 5

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 5
    Mostrando versículos 10–22 de 22

    10Ẹran-ara wa gbóná bí ààrò,ebi sì yó wa bí àárẹ̀.

    16Adé ti ṣí kúrò ní orí waègbé ni fún wa, nítorí a ti ṣẹ̀.

    22àyàfi tí o bá ti kọ̀ wá sílẹ̀ pátápátátí ìbínú rẹ sí wa sì kọjá ìwọ̀n.

  12. Romanos 15

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 15
    Mostrando versículos 9–33 de 33

    915.9: Sm 18.49; 2Sa 22.50.kí àwọn aláìkọlà kí ó lè yin Ọlọ́run lógo nítorí àánú rẹ̀; gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé:"Nítorí èyí ni èmi ó ṣe yìn ọ́ láàrín àwọn Kèrí,Èmi ó sì kọrin sí orúkọ rẹ."

    10 15.10: De 32.43. Ó sì tún wí pé,"Ẹ̀yin Kèrí, ẹ ma yọ̀, pẹ̀lú àwọn ènìyàn rẹ̀."

    11"Ẹyin Olúwa, gbogbo ẹ̀yin Kèrí;

    12dìde ṣe àkóso àwọn Kèrí;Àwọn Kèrí yóò ní ìrètí nínú

    1615.16: Ap 9.15.láti jẹ́ ìránṣẹ́ Kristi Jesu láàrín àwọn Kèrí láti polongo ìyìnrere Ọlọ́run gẹ́gẹ́ bí ojúṣe àlùfáà, kí àwọn Kèrí lè jẹ́ ẹbọ ọrẹ ìtẹ́wọ́gbà fún Ọlọ́run, èyí tí a ti fi Ẹ̀mí Mímọ́ yà sí mímọ́.

    18ṣe, ní títọ́ àwọn Kèrí ṣọ́nà láti ṣe ìgbọ́ràn

    27pé a fi àwọn Kèrí ṣe alájọni nínú ohun

    3315.33: 2Kọ 13.11; Fp 4.9.Kí Ọlọ́run àlàáfíà wà pẹ̀lú gbogbo yín. Àmín.

  13. Habacuque 1

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 1
    Mostrando versículos 1–5 de 17

    1Àsọtẹ́lẹ̀ tí wòlíì Habakuku rí.

    2 1.2: Isa 13.1–14.23; 47; Jr 50–51. Olúwa, èmi yóò ti ké pẹ́ tó fún ìrànlọ́wọ́,ṣùgbọ́n ti ìwọ kò ni fetí sí mi?Tàbí kígbe sí ọ ní ti, "Ìwà ipá!"Ṣùgbọ́n tí ìwọ kò sì gbàlà?

    5 1.5: Ap 13.41. "Ẹ wo inú àwọn kèrí, ki ẹ sí wòye,kí háà kí ó sì ṣe yin gidigidi.Nítorí èmi ó ṣe ohun kan ní ọjọ́ yíntí ẹ̀yin kò jẹ́ gbàgbọ́,bí a tilẹ̀ sọ fún yin.

  14. Jeremias 35

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 35
    Mostrando versículos 7–14 de 19

    7Bẹ́ẹ̀ ni, ẹ̀yin kò gbọdọ̀ kọ́ ilé tàbí kí ẹ fúnrúgbìn, tàbí kí ẹ gbin ọgbà àjàrà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin kò gbọdọ̀ ní ọ̀kankan nínú àwọn ohun wọ̀nyí, ṣùgbọ́n ní gbogbo ọjọ́ yín ni ẹ̀yin ó máa gbé inú àgọ́; kí ẹ̀yin kí ó lè wá ní ọjọ́ púpọ̀ ní ilẹ̀ náà; níbi tí ẹ̀yin ti ń ṣe àtìpó.’

    12Nígbà yìí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wá wí pé:

    14‘Ọ̀rọ̀ Jehonadabu ọmọ Rekabu tí ó pàṣẹ fún àwọn ọmọ rẹ̀ pé wọn kò gbọdọ̀ mu ọtí wáìnì, ni a mú ṣẹ, wọn kò sì mu ọtí wáìnì títí di òní yìí, nítorí tí wọ́n gba òfin baba wọn. Èmi sì ti ń sọ̀rọ̀ fún un yín, ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò fetí sí mi.

  15. Isaías 8

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 8
    Mostrando versículos 5–16 de 22

    5Olúwa sì tún sọ fún mi pé,

    13Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni Ẹni tí ìwọ yóò kà sí mímọ́,Òun ni kí o bẹ̀rùÒun ni kí àyà rẹ̀ fò ọ́,

    16Di májẹ̀mú náàkí o sì fi èdìdì di òfin náà láàrín àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mi.

  16. Lucas 21

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 21
    Mostrando versículos 18–27 de 38

    1821.18: Lk 12.7; Mt 10.30; Ap 27.34; 1Sa 14.45.Ṣùgbọ́n irun orí yín kan kì yóò ṣègbé.

    1921.19: Mt 10.22; If 2.7.Nínú ìdúró ṣinṣin yín ni ẹ̀yin ó jèrè ọkàn yín.

    2721.27: Lk 9.27; Da 7.13-14.Nígbà náà ni wọn ó sì rí Ọmọ Ènìyàn tí yóò máa bọ̀ wá nínú àwọsánmọ̀ pẹ̀lú agbára àti ògo ńlá.

  17. 2 Coríntios 13

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 13
    Mostrando versículos 5–13 de 14

    5Ẹ máa wádìí ara yín, bí ẹ̀yin bá wà nínú ìgbàgbọ́; ẹ máa dán ara yín wò. Tàbí ẹ̀yin fúnra yín kò mọ ara yín pé Jesu Kristi wá nínú yín? Àfi bí ẹ̀yin bá jẹ́ àwọn tí a tanù.

    12 13.12: Ro 16.16. Ẹ fi ìfẹnukonu mímọ́ kí ara yín.

    13 13.13: Fp 4.22. Gbogbo àwọn ènìyàn Ọlọ́run níbi kí i yín.

  18. 2 Pedro 1

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 1
    Mostrando versículos 1–7 de 21

    1Simoni Peteru, ìránṣẹ́ àti aposteli Jesu Kristi,Sí àwọn tí ó gba irú iyebíye ìgbàgbọ́ kan náà pẹ̀lú wá nínú òdodo Ọlọ́run wa àti ti Jesu Kristi Olùgbàlà:

    6àti àìrékọjá kún ìmọ̀; àti sùúrù kún àìrékọjá; àti ìwà-bí-Ọlọ́run kún sùúrù.

    7Àti ìfẹ́ ọmọnìkejì kún ìwà-bí-Ọlọ́run; àti ìfẹ́ni kún ìfẹ́ ọmọnìkejì.

  19. Apocalipse 2

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 2
    Mostrando versículos 1–29 de 29

    1"Sí angẹli ìjọ ní Efesu kọ̀wé:Nǹkan wọ̀nyí ní ẹni tí ó mú ìràwọ̀ méje náà ni ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ wí, ẹni tí ń rìn ní àárín ọ̀pá wúrà fìtílà méje.

    25ṣùgbọ́n èyí tí ẹ̀yin ní, ẹ di mú ṣinṣin títí èmi ó fi dé.

    29Ẹni tí ó bá létí, kí ó gbọ́ ohun tí Ẹ̀mí ń sọ fún àwọn ìjọ.

  20. Josué 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 2–11 de 17

    2Lẹ́yìn ọjọ́ kẹta àwọn olórí la àárín ibùdó já.

    10Èyí ni ẹ̀yin yóò fi mọ̀ pé Ọlọ́run alààyè wà ní àárín yín àti pé dájúdájú yóò lé àwọn ará Kenaani, àwọn ará Hiti, Hifi, Peresi, Girgaṣi, Amori àti Jebusi jáde níwájú u yín.

    11Àpótí májẹ̀mú Olúwa gbogbo ayé ń gòkè lọ sí Jordani ṣáájú u yín.

Léxico (correspondência exata) Semântico (correspondência relacionada) Versículos omitidos Contexto do capítulo