Publicidade

Cânticos 8

1 Ìwọ ìbá arákùnrin mi si mi,

èyí ó ọmú ìyá mi dàgbà!

Èmi ìbá òde,

èmi ìbá fi ẹnu ́ ẹnu,

wọn fi ṣe ẹlẹ́.

2 Èmi ìbá fi ̀hàn ́

èmi ìbá sínú ilé ìyá mi,

ìwọ ìbá kọ́ mi.

Èmi ìbá fi ọtí wáìnì olóòórùn dídùn fún mu,

àti oje èso pomegiranate mi.

3 Ọwọ́ òsì rẹ ìbá abẹ́ orí mi,

ọwọ́ ̀tún rẹ ìbá gbà mọ́ra.

4 Ọmọbìnrin Jerusalẹmu, èmi yín ìjà.

ṣe olùfẹ́ mi sókè.

ṣe i títí yóò fi ú.

̀rẹ́

5 Ta ni ẹni ń gòkè bọ̀ láti aginjù,

ó fi ara ti olùfẹ́ rẹ̀.

Olólùfẹ́

abẹ́ igi ápù ni mo ti dìde; níbẹ̀ ni ìyá rẹ ti lóyún rẹ

níbẹ̀ ni ẹni ń rọbí .

6 Gbé mi àyà rẹ èdìdì

èdìdì apá rẹ;

nítorí ìfẹ́ lágbára ikú,

ìjowú le isà òkú

jíjò rẹ̀ jíjò iná,

gẹ́gẹ́ ̀wọ́-iná Olúwa.

7 Omi púpọ̀ le paná ìfẹ́;

bẹ́̀ ni gbígbá omi le gbá a lọ.

ènìyàn fún ìfẹ́,

gbogbo ọrọ̀ ilé rẹ̀,

a ó kẹ́gàn rẹ̀ pátápátá.

̀rẹ́

8 Àwa arábìnrin kékeré kan,

òun ọmú,

ni àwa yóò fún arábìnrin wa,

ọjọ́ a ó fẹ́ ?

9 òun jẹ́ ògiri,

àwa yóò kọ́ ilé odi fàdákà e lórí.

òun jẹ́ ìlẹ̀kùn,

àwa yóò fi pákó kedari i.

Olólùfẹ́

10 Èmi jẹ́ ògiri,

ọmú mi ilé ìṣọ́

bẹ́̀ ni mo ṣe ojú rẹ̀

ẹni ń àlàáfíà .

11 Solomoni ọgbà àjàrà kan Baali-Hamoni

ó gbé ọgbà àjàrà rẹ̀ fún àwọn alágbàtọ́

olúkúlùkù ni ó ń èso rẹ̀

ẹgbẹ̀rún (1,000) fàdákà.

12 Ṣùgbọ́n ọgbà àjàrà mi jẹ́ tèmi, ó fún mi;

ẹgbẹ̀rún ṣékélì jẹ́ tìrẹ, ìwọ Solomoni,

igba jẹ́ ti àwọn alágbàtọ́èso.

Olùfẹ́

13 Ìwọ ń gbé inú ọgbà,

àwọn ̀rẹ́ rẹ dẹtí ohùn rẹ,

jẹ́ èmi náà gbọ́ ohùn rẹ!

Olólùfẹ́

14 Yára , Olùfẹ́ mi,

ìwọ ó abo egbin,

tàbí gẹ́gẹ́ ọmọ àgbọ̀nrín,

lórí òkè òórùn dídùn.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-