Publicidade

Eclesiastes 11

Àkàrà lórí omi

1 Fún àkàrà rẹ sórí omi,

nítorí lẹ́yìn ọjọ́ púpọ̀, ìwọ yóò i padà.

2 Fi ìpín fún méje, àní fún mẹ́jọ pẹ̀,

nítorí ìwọ mọ ohun ìparun ó le è sórí ilẹ̀.

3 àwọsánmọ̀ kún fún omi,

ayé ni wọ́n ń rọ òjò .

igi ìhà gúúsù tàbí ìhà àríwá,

níbi ó náà, ni yóò dùbúlẹ̀ .

4 Ẹnikẹ́ni ó ń wo afẹ́fẹ́ fúnrúgbìn;

ẹnikẹ́ni ó ń wo àwọsánmọ̀ kórè.

5 Gẹ́gẹ́ ìwọ ti ṣe mọ ojú ̀afẹ́fẹ́

tàbí mọ ọmọ ń dàgbà nínú ikùn ìyáarẹ̀,

bẹ́̀ náà ni ìwọ le è òye iṣẹ́ Ọlọ́run

ẹlẹ́dàá ohun gbogbo.

6 Fún irúgbìn rẹ òwúrọ̀ kùtùkùtù,

ṣe jẹ́ ọwọ́ rẹ ṣọlẹ̀ àṣálẹ́,

nítorí ìwọ mọ èyí yóò ṣe rere

bóyá èyí tàbí ìyẹn

tàbí àwọn méjèèjì ni yóò ṣe dáradára bákan náà.

Rántí ẹlẹ́dàá rẹ ìgbà èwe rẹ

7 Ìmọ́lẹ̀ dùn;

Ó dára fún ojú láti oòrùn.

8 Ṣùgbọ́n jẹ́ ènìyàn jẹ̀gbádùn gbogbo iye ọdún

ó le è láyé

ṣùgbọ́n jẹ́ ó rántí ọjọ́ òkùnkùn

nítorí wọn ó pọ̀.

Gbogbo ohun ó ń bọ̀ asán ni.

9 Jẹ́ inú rẹ dùn, ìwọ ̀dọ́mọdé ìgbà o èwe

o jẹ́ ọkàn rẹ fún ayọ̀ ìgbà èwe rẹ.

Tẹ̀̀ọkàn rẹ

àti ohunkóhun ojú rẹ

ṣùgbọ́n mọ̀ dájú nípa gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni

Ọlọ́run yóò ìdájọ́.

10 Nítorí náà, ìjayà kúrò ọkàn rẹ

o ìbànújẹ́ ara rẹ kúrò

nítorí èwe àti kékeré ìtumọ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-