Publicidade

Eclesiastes 4

Ìnilára, làálàá, àti àìlọ́rẹ̀́

1 Mo tún ó, mo gbogbo ìnilára ó ń ṣẹlẹ̀ lábẹ́ oòrùn,

mo ẹkún àwọn ara ń ni,

wọn olùtùnú kankan,

agbára ìkápá àwọn ó ń ni wọ́n lára,

wọn olùtùnú kankan.

2 Mo jowú àwọn wọ́n ti

wọ́n ti lọ,

ó sàn fún wọn ju àwọn

wọ́n láààyè lọ.

3 Nítòótọ́, ẹni ì sàn ju

àwọn méjèèjì lọ:

ẹni ì iṣẹ́ búburú

ó ń lọ abẹ́ oòrùn.

4 Mo tún mọ̀ pẹ̀, ìdí ènìyàn fi ń ṣiṣẹ́ tagbára tagbára láti ṣe àṣeyọrí, nítorí wọn ń jowú àwọn aládùúgbò wọn ni. Ṣùgbọ́n, asán ni, ó dàbí ẹni ń gbìyànjú àti afẹ́fẹ́.

5 Aṣiwèrè ọwọ́ rẹ̀

ó ba tara rẹ̀ jẹ́.

6 Oúnjẹ ̀kúnwọ́ kan pẹ̀ìdákẹ́ jẹ́́jẹ́ sàn ju ̀kúnwọ́ méjì pẹ̀wàhálà,

àti gbígba ìyànjú àti afẹ́fẹ́ lọ.

7 Lẹ́̀kan i, mo tún ohun asán kan lábẹ́ oòrùn.

8 Ọkùnrin kan ṣoṣo ;

ọmọkùnrin kankan tàbí ẹbí.

òpin nínú làálàá rẹ̀ gbogbo,

síbẹ̀, ọrọ̀ tẹ́ ojú rẹ̀ lọ́rùn.

Bẹ́̀ ni , "Nítorí ta ni èmí ṣe ń ṣe làálàá,

àti , èétiṣe mo fi ń fi ìgbádùn du ara mi?"

Eléyìí náà asán ni,

iṣẹ́ òsì!

9 Ẹni méjì sàn ju ẹnìkan,

nítorí wọ́n èrè rere fún làálàá wọn.

10 ̀kan ṣubú lulẹ̀,

̀rẹ́ rẹ̀ le è ràn án lọ́wọ́ ó á sókè,

ṣùgbọ́n ìyọnu ni fún ọkùnrin náà ó ṣubú

ẹni ó le è ràn án lọ́wọ́!

11 Àti pẹ̀, ẹni méjì sùn pọ̀, wọn yóò móoru.

Ṣùgbọ́n báwo ni ẹnìkan ṣe le è nìkan móoru?

12 ó tilẹ̀ jẹ́ , a le è kojú ogun ẹnìkan,

àwọn méjì le è gbìjà ara wọn,

ìkọ́ okùn mẹ́ta í dùn ún yára .

Asán ni ipò gíga

13 Òtòṣì ìpẹ́̀rẹ̀ ó ṣe ọlọ́gbọ́n, ó sàn ju arúgbó àti aṣiwèrè ọba lọ mọ yóò ti ṣe gba ìmọ̀ràn. 14 Nítorí láti inú túbú ni ó ti jáde láti jẹ ọba, a tilẹ̀ i tálákà ìjọba rẹ̀. 15 Mo gbogbo alààyè ń rìn lábẹ́ oòrùn, pẹ̀ìpẹ́̀rẹ̀ kejì yóò gba ipò ọba yìí. 16 Gbogbo àwọn ó níwájú wọn lópin, ̀gọ̀̀rọ̀ àwọn ènìyàn ó jẹ ọba lórí, ẹni ó ipò yìí dùn mọ́ àwọn ó tẹ̀wọn nínú. Asán ni eléyìí pẹ̀jẹ́, ó dàbí ẹni ń gbìyànjú àti afẹ́fẹ́ ni.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-