Pular para o conteúdo
Publicidade

Ester 7

Síso Hamani rọ̀

1 Ọba àti Hamani lọ àpèjẹ pẹ̀Esteri ayaba, 2 7.2: Mk 6.23.wọ́n ṣe ń mu wáìnì ọjọ́ kejì yìí, ọba tún béèrè , "Esteri ayaba, ni ̀bẹ̀ rẹ? A ó fi fún . ni ìbéèrè rẹ? ó tilẹ̀ jẹ́ ìdajì ìjọba à mi, n ó fi fún ."

3 Nígbà náà ni ayaba Esteri dáhùn, "èmi ojúrere rẹ, ìwọ ọba, ó tẹ́ ọláńlá à rẹ lọ́rùn, fún mi ̀mi, èyí ni ̀bẹ̀ mi. o pa àwọn ènìyàn mi mọ́—èyí ni ìbéèrè mi. 4 Nítorí a ti ta èmi àti àwọn ènìyàn mi fún àwọn yóò pa run, à ti ṣe ìdájọ́ wa fún pípa àti píparẹ́. a tilẹ̀ ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin, ǹ dákẹ́, nítorí irú ìpọ́njú bẹ́̀ èyí à ń yọ ọba lẹ́nu ."

5 Ọba Ahaswerusi bi Esteri ayaba léèrè , "Ta a ni ẹni náà? Níbo ni ẹni náà bẹ̀láti ṣe irú nǹkan bẹ́̀?"

6 Esteri sọ , "Alátakò àti ̀náà ni Hamani aláìníláárí yìí."

Nígbà náà ni Hamani wárìrì níwájú ọba àti ayaba. 7 Ọba dìde pẹ̀ìbínú, ó fi wáìnì sílẹ̀ ó jáde lọ àgbàlá ààfin. Ṣùgbọ́n nígbà Hamani, ti i dájú ọba ti pinnu láti pa òun, ó dúró lẹ́yìn láti bẹ Esteri ayaba nítorí ̀rẹ̀.

8 ọba ṣe padà láti àgbàlá ààfin gbọ̀ngàn àsè náà, Hamani ṣubú sórí àga Esteri ayaba fẹ̀yìn .

Ọba pariwo , "Yóò ha tún tẹ́ ayaba níbí yìí, nínú ilé, ojú mi ?"

kété ọba sọ ̀rọ̀ yìí jáde, wọ́n da aṣọ bo Hamani lójú. 9 Nígbà náà Harbona ̀kan nínú àwọn ìwẹ̀ń dúró níwájú ọba, sọ , "Igi ó ga ìwọ̀n ẹsẹ̀ bàtà marunlélaadọrin ni Hamani ti ̀gbẹ́ ilé e rẹ̀. Ó ṣe é fún Mordekai, ẹni ó sọ̀rọ̀ jáde láti ṣe ìrànlọ́wọ́ fún ọba."

Ọba , so ó rọ̀ sórí i rẹ́! 10 Wọ́n so Hamani sórí igi ó ti pèsè sílẹ̀ fún Mordekai, ìbínú ọba rọ̀.

Veja também