Publicidade

Hebreus 13

Ìparí àwọn ̀rọ̀ ìyànjú náà

1 ìfẹ́ ará o títí. 2 13.2: Gẹ 18.1-8; 19.1-3.ṣe gbàgbé láti máa ṣe àlejò; nítorí nípa bẹ́̀ ni àwọn ẹlòmíràn ṣe àwọn angẹli àlejò láìmọ̀. 3 máa rántí àwọn òǹdè ẹni a pẹ̀wọn, àti àwọn a ń pọn lójú ̀yin tìkára yín pẹ̀ń bẹ nínú ara.

4 ìgbéyàwó lọ́láàrín gbogbo ènìyàn, àkéte si jẹ́ aláìléèérí, nítorí àwọn àgbèrè àti àwọn panṣágà ni Ọlọ́run yóò lẹ́jọ́. 5 13.5: De 31.6,8; Jo 1.5.ọkàn yín ṣe ìfẹ́ owó, ki ohun yin; nítorí òun tìkára rẹ̀ ti ,

"Èmi jẹ́ fi ́ sílẹ̀,

bẹ́̀ ni èmi jẹ́ kọ̀ ́ sílẹ̀."

6 13.6: Sm 118.6. Nítorí náà ni àwa ṣe ń fi ìgboyà ,

"Olúwa ni olùrànlọ́wọ́ mi, èmi yóò bẹ̀;

kín ni ènìyàn ṣe mi?"

7 máa rántí àwọn tiwọn jẹ́ aṣáájú yín, tiwọn ti sọ ̀rọ̀ Ọlọ́run fún yín; máa ro òpin ìwà ayé wọn, máa ṣe àfarawé ìgbàgbọ́ wọn. 8 Jesu Kristi ̀kan náà ni lánàá, àti lónìí, àti títí láé.

9 ṣe jẹ́ a fi onírúurú àti àjèjì ̀kọ́ gbá yin kiri. Nítorí ó dára a yin lọ́kàn le nípa oore-ọ̀fẹ́, í ṣe nípa oúnjẹ nínú èyí àwọn ó ti rìn nínú wọn èrè. 10 Àwa pẹpẹ kan, níbi èyí àwọn ti ń sin àgọ́ ni agbára láti máa jẹ.

11 13.11,13: Le 16.27. Nítorí nígbà olórí àlùfáà ̀jẹ̀ àwọn ẹran si Ibi Mímọ́ Jùlọ gẹ́gẹ́ ìrúbọ ̀ṣẹ̀, òkú àwọn ẹran náà ni a o sun lẹ́yìn ibùdó. 12 Nítorí náà Jesu pẹ̀, ó fi ̀jẹ̀ ara rẹ̀ sọ àwọn ènìyàn di mímọ́, ó jìyà lẹ́yìn ibodè. 13 Nítorí náà jẹ́ a jáde tọ̀ ́ lọ lẹ́yìn ibùdó, a máa ru ̀gàn rẹ̀. 14 Nítorí àwa ìlú o wa títí níhìn-ín, ṣùgbọ́n àwa ń èyí ń bọ.

15 13.15: Le 7.12; Isa 57.19; Ho 14.2. Ǹjẹ́ nípasẹ̀ rẹ̀, jẹ́ a máa ẹbọ ìyìn si Ọlọ́run nígbà gbogbo, èyí yìí ni èso ètè wa, ń jẹ́wọ́ orúkọ rẹ̀. 16 Ṣùgbọ́n ṣe gbàgbé láti máa ṣoore àti láti máa pín fun ni nítorí irú ẹbọ wọ̀nyí ni inú Ọlọ́run dùn jọjọ.

17 máa gbọ́ ti àwọn ń ṣe olórí yín, máa tẹríba fún wọ́n, nítorí wọn ń ṣọ́ ̀ṣọ́ nítorí ọkàn yín, àwọn ti yóò ṣe ìṣirò, wọn fi ayọ̀ ṣe èyí, í ṣe pẹ̀ìbànújẹ́, nítorí èyí yìí yóò jẹ àìlérè fún yín.

18 máa gbàdúrà fún wa, nítorí àwa gbàgbọ́ àwa ni ̀ọkàn rere, a ń fẹ́ láti máa hùwà títọ́ nínú ohun gbogbo. 19 Ṣùgbọ́n èmi ń bẹ̀ yín gidigidi i láti máa ṣe èyí, a ba tètè fi mi fún yín padà.

20 13.20: Isa 63.11; Sk 9.11; Isa 55.3; El 37.26. Ǹjẹ́ Ọlọ́run àlàáfíà, ẹni o tún mu olùṣọ́-àgùntàn ńlá ti àwọn àgùntàn, ti inú òkú , nípa ̀jẹ̀ májẹ̀ayérayé, àní Olúwa wa Jesu. 21 ó yín nínú iṣẹ́ rere gbogbo láti ṣe ìfẹ́ rẹ̀, ó máa ṣiṣẹ́ ohun i ṣe ìtẹ́wọ́gbà níwájú rẹ̀ nínú yín nípasẹ̀ Jesu Kristi; ẹni ògo fún láé àti láéláé. Àmín.

22 Èmi ń bẹ̀ yín ará, gbà ̀rọ̀ ìyànjú mi; nítorí ìwé kúkúrú ni mo kọ yín.

23 mọ a titu Timotiu arákùnrin wa sílẹ̀; ó ba tètè , èmí pẹ̀rẹ̀ yóò yín, àti gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́.

24 ki gbogbo àwọn ń ṣe olórí yín, àti gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́.

Àwọn o ti Itali ki yín.

25 oore-ọ̀fẹ́ pẹ̀gbogbo yín.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-