Publicidade

Lucas 11

Jesu ń kọ́ ̀kọ́ nípa àdúrà

1 ó ti ń gbàdúrà ibi kan, ó ti dákẹ́, ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ fún un , "Olúwa, kọ́ wa a ti ń gbàdúrà, Johanu ti kọ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀."

2 Ó fún wọn , "Nígbà ̀yin ń gbàdúrà, máa :

" Baba wa ń bẹ ̀run,

á bọ̀wọ̀ fún orúkọ yín.

ìjọba yín , ìfẹ́ tiyín ni a ṣe,

i ti ọrun, bẹ́̀ ni ayé.

3 Fún wa oúnjẹ òòjọ́ wa lójoojúmọ́.

4 o dárí ̀ṣẹ̀ wa ;

nítorí àwa tìkára wa pẹ̀a máa dáríjì olúkúlùkù ẹni ó jẹ gbèsè,

sínú ìdánwò, ṣùgbọ́n gbà lọ́wọ́ ẹni búburú ni.’ "

5 Ó fún wọn , "Ta ni nínú yín yóò ̀rẹ́ kan, yóò tọ̀ ́ lọ láàrín ̀gànjọ́, yóò fún un , ̀rẹ́, mi ìṣù àkàrà mẹ́ta. 6 Nítorí ̀rẹ́ mi kan ti àjò sọ́dọ̀ mi, èmi nǹkan èmi ó gbé kalẹ̀ níwájú rẹ̀.’ 7 òun ó gbé inú ilé dáhùn fún un , yọ lẹ́nu, a ti ìlẹ̀kùn, àwọn ọmọ mi si ń bẹ lórí ẹní pẹ̀mi: èmi dìde fi fún ! 8 Mo fún yín, òun tilẹ̀ ti fẹ́ dìde ó fi fún un nítorí í ṣe ̀rẹ́ rẹ̀, ṣùgbọ́n nítorí àwíìyánnu rẹ̀, yóò dìde, yóò fún un ó ti ń fẹ́.

9 "Èmí fún yín, béèrè, a ó fi fún un yín; kiri, ̀yin ó ; kànkùn, a ó ṣí i sílẹ̀ fún yín. 10 Nítorí ẹnikẹ́ni ó béèrè, ó gbà; ẹni ó ń kiri, ó ; àti ẹni ó kànkùn ni a ó ṣí i sílẹ̀ fún.

11 "Ta ni baba nínú yín ọmọ rẹ̀ yóò béèrè àkàrà lọ́dọ̀ rẹ̀, yóò fún un òkúta? Tàbí ó béèrè ẹja, yóò fún un ejò? 12 Tàbí ó béèrè ̀yin, yóò fún un àkéekèe? 13 Ǹjẹ́ ̀yin ó jẹ́ ènìyàn búburú mọ a ti í fi ̀bùn dáradára fún àwọn ọmọ yín, mélòó mélòó ha ni Baba yín ń bẹ ̀run yóò fi ̀Mímọ́ rẹ̀ fún àwọn ó béèrè lọ́dọ̀ rẹ̀!"

Jesu àti Beelsebulu

14 Ó ń ̀èṣù kan jáde, ó yadi. Nígbà ̀èṣù náà jáde, odi sọ̀rọ̀; ẹnu ya ìjọ ènìyàn. 15 Ṣùgbọ́n àwọn ẹlòmíràn nínú wọn , "Nípa Beelsebulu olórí àwọn ̀èṣù ni ó fi ń àwọn ̀èṣù jáde." 16 Àwọn ẹlòmíràn ń dán an , wọ́n ń fẹ́ àmì lọ́dọ̀ rẹ̀ láti ̀run .

17 Ṣùgbọ́n òun mọ èrò inú wọn, ó fún wọn , "Gbogbo ìjọba ó ya ara rẹ̀ ipá, ni a ń sọ di ahoro; ilé ó ya ara rẹ̀ nípá yóò . 18 Satani ba yapa ara rẹ̀, ìjọba rẹ̀ yóò ha ṣe dúró? Nítorí ̀yin , nípa Beelsebulu ni èmi fi ń àwọn ̀èṣù jáde. 19 ó ba ṣe nípa Beelsebulu ni èmi fi ń àwọn ̀èṣù jáde, nípa ta ni àwọn ọmọ yín fi ń wọn jáde, nítorí náà àwọn ni yóò ṣe onídàájọ́ yín. 20 Ṣùgbọ́n ó ṣe nípa ìka ọwọ́ Ọlọ́run ni èmi fi ń àwọn ̀èṣù jáde, ǹjẹ́ ìjọba Ọlọ́run yín tán.

21 "Nígbà alágbára ọkùnrin ó ni ìhámọ́ra ń ṣọ́ ààfin rẹ̀, ẹrù rẹ̀ yóò àlàáfíà. 22 Ṣùgbọ́n nígbà ẹni ó agbára ú kọlù ú, ó ṣẹ́gun rẹ̀ a gba gbogbo ìhámọ́ra rẹ̀ ó gbẹ́kẹ̀lọ́wọ́ rẹ̀, a pín ìkógun rẹ̀.

23 "Ẹni pẹ̀mi, ó lòdì mi, ẹni mi kójọpọ̀, ó fọ́nká.

24 "Nígbà ̀àìmọ́ jáde kúrò lára ènìyàn, a máa rìn kiri ibi gbígbẹ, a máa ibi ìsinmi; nígbà , a , Èmi yóò padà lọ ilé mi ibi mo gbé ti jáde . 25 Nígbà ó , ó a gbá a, a ṣe é ̀ṣọ́. 26 Nígbà náà ni yóò lọ, yóò ̀méje mìíràn ó burú ju òun tìkára rẹ̀ lọ , wọn yóò wọlé, wọn yóò máa gbé níbẹ̀, ìgbẹ̀yìn ọkùnrin náà yóò burú ju ìṣáájú rẹ̀ lọ."

27 ó ti ń sọ nǹkan wọ̀nyí, obìnrin kan gbóhùn rẹ̀ sókè nínú ìjọ, ó fún un , "Ìbùkún ni fún inú ó , àti ọmú ìwọ mu!"

28 Ṣùgbọ́n òun , nítòótọ́, ó kúkú , "Ìbùkún ni fún àwọn ń gbọ́ ̀rọ̀ Ọlọ́run, wọ́n pa á mọ́!"

Àmì ti Jona

29 Nígbà ìjọ ènìyàn ṣùjọ ̀dọ̀ rẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ , "Ìran búburú ni èyí, wọ́n ń àmì; a yóò fi àmì kan fún un ṣe àmì Jona wòlíì! 30 Nítorí Jona ti jẹ́ àmì fún àwọn ará Ninefe, gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni Ọmọ Ènìyàn yóò ṣe jẹ́ àmì fún ìran yìí. 31 Ọbabìnrin gúúsù yóò dìde ọjọ́ ìdájọ́ pẹ̀àwọn ènìyàn ìran yìí, yóò wọn lẹ́bi: nítorí ó ti ìhà ìpẹ̀kun ayé láti gbọ́ ọgbọ́n Solomoni: kíyèsi i, ẹni ó pọ̀Solomoni lọ ń bẹ níhìn-ín yìí. 32 Àwọn ará Ninefe yóò dìde ọjọ́ ìdájọ́ pẹ̀ìran yìí, wọn ó a lẹ́bi: nítorí wọn ronúpìwàdà nípa ìwàásù Jona; kíyèsi i, ẹni ó pọ̀Jona lọ ń bẹ níhìn-ín yìí.

Òwe nípa fìtílà a tàn

33 "ẹnìkan, nígbà ó tan fìtílà tan, gbé e ìkọ̀kọ̀, tàbí sábẹ́ òsùwọ̀n, ṣe sórí ̀fìtílà, àwọn ń wọlé ba à máa ìmọ́lẹ̀. 34 Ojú ni fìtílà ara: ojú rẹ mọ́lẹ̀ kedere, gbogbo ara rẹ a mọ́lẹ̀; ṣùgbọ́n ojú rẹ ṣókùnkùn, ara rẹ pẹ̀a kún fún òkùnkùn. 35 Nítorí náà kíyèsi i, ìmọ́lẹ̀ ń bẹ nínú rẹ ṣe di òkùnkùn. 36 Ǹjẹ́ gbogbo ara rẹ kún fún ìmọ́lẹ̀, apá kan ó ṣókùnkùn, gbogbo rẹ̀ ni yóò ìmọ́lẹ̀, gẹ́gẹ́ ìgbà fìtílà fi ìtànṣán rẹ̀ fún ìmọ́lẹ̀."

Ègún mẹ́

37 ó ti ń , Farisi kan bẹ̀ ́ ó òun jẹun: ó wọlé, ó jókòó láti jẹun. 38 Nígbà Farisi náà i, ẹnu á nítorí kọ́kọ́ wẹ ọwọ́ ó jẹun.

39 Olúwa fún un , "̀yin Farisi a máa ń fọ òde ago àti àwopọ̀kọ́: ṣùgbọ́n, inú yín kún fún ìwà búburú àti ìrẹ́jẹ. 40 ̀yin aṣiwèrè, ẹni ó ṣe èyí ń bẹ lóde, òun ha ṣe èyí ń bẹ nínú pẹ̀? 41 Nípa ohun ti inú yin, ki ̀yin kúkú máa ṣe ìtọrẹ àánú nínú ohun ̀yin , kíyèsi i, ohun gbogbo ni ó di mímọ́ fún yín.

42 "Ṣùgbọ́n ègbé ni fún yín, ̀yin Farisi, nítorí ̀yin a máa san ìdámẹ́wàá minti àti irúgbìn, àti gbogbo ewébẹ̀, ṣùgbọ́n ̀yin kọ ìdájọ́ àti ìfẹ́ Ọlọ́run: wọ̀nyí jẹ́ ohun gbọdọ̀ ṣe, láìsí fi àwọn ìyókù sílẹ̀ láìṣe.

43 "Ègbé ni fún yín, ̀yin Farisi, àgàbàgebè! Nítorí ̀yin fẹ́ ipò ọlá nínú Sinagọgu, àti ìkíni ọjà.

44 "Ègbé ni fún un yín, nítorí ̀yin dàbí ibojì farahàn, àwọn ènìyàn ń rìn lórí rẹ̀ láìmọ̀."

45 Nígbà náà ni ̀kan nínú àwọn amòfin dáhùn, ó fún un , "Olùkọ́, nínú èyí ìwọ ń yìí ìwọ ń gan àwa pẹ̀."

46 Ó , "Ègbé ni fún ̀yin amòfin pẹ̀, nítorí ̀yin di ẹrù ó wúwo láti ènìyàn lórí, bẹ́̀ ni ̀yin tìkára yín jẹ́ fi ìka yín kan ẹrù náà.

47 "Ègbé ni fún yín, nítorí ̀yin kọ́ ibojì àwọn wòlíì, àwọn baba yín pa. 48 Ǹjẹ́ ̀yin jẹ́ ẹlẹ́rìí, inú dídùn iṣẹ́ àwọn baba yín, nítorí wọn pa wọ́n, ̀yin kọ́ ibojì wọn. 49 Nítorí èyí ni ọgbọ́n Ọlọ́run ṣe , Èmi ni ó rán àwọn wòlíì àti àwọn aposteli wọn, wọn ó ṣe inúnibíni wọn. 50 a béèrè ̀jẹ̀ àwọn wòlíì gbogbo, a ti ta sílẹ̀ láti ìgbà ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé , lọ́wọ́ ìran yìí; 51 láti ̀jẹ̀ Abeli , títí ó fi ̀jẹ̀ Sekariah, ó ṣègbé láàrín pẹpẹ àti tẹmpili. Lóòótọ́ ni mo fún yín ìran yìí ni yóò ru gbogbo ̀bi àwọn nǹkan wọ̀nyí.

52 "Ègbé ni fún yín, ̀yin amòfin, nítorí ̀yin ti kọ́kọ́rọ́ ìmọ̀ kúrò; ̀yin tìkára yín wọlé, àwọn ń wọlé, ni ̀yin ń lọ́wọ́."

53 ó ti ń lọ kúrò níbẹ̀, àwọn akọ̀àti àwọn Farisi bẹ̀rẹ̀ bi í lọ́rọ̀ gidigidi, wọ́n ń yọ ́ lẹ́nu láti nǹkan púpọ̀. 54 Wọ́n ń ṣọ́ , wọ́n ń ̀láti nǹkan gbámú lẹ́nu wọn à fi ̀sùn kàn án.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-