Publicidade

Lamentações 2

1 Báwo ni Olúwa ṣe bo ọmọbìnrin Sioni

pẹ̀àwọsánmọ̀ ìbínú rẹ̀!

Ó sọ ògo Israẹli kalẹ̀,

láti ̀run ayé;

rántí àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀

ọjọ́ ìbínú rẹ̀.

2 Láìní àánú ni Olúwa gbé

ibùgbé Jakọbu ;

nínú ìrunú rẹ̀, ni ó

ibi gíga ọmọbìnrin Juda lulẹ̀.

Ó ti ìjọba àti àwọn ọmọ-aládé ọkùnrin

lọ sínú ilẹ̀ àìlọ́wọ̀.

3 ìbínú gbígbóná rẹ̀ ni ó

gbogbo ìwo Israẹli.

Ó ti ọwọ́ ̀tún rẹ̀ kúrò

nígbà àwọn ̀.

Ó run Jakọbu ̀wọ́-iná

àgọ́ àwọn ọmọbìnrin Sioni.

4 Ó na ọfà rẹ̀ ̀;

ọwọ́ ̀tún rẹ̀ múra.

ti ̀ó ti parun

ó ìbínú rẹ̀ jáde iná

sórí àgọ́ ọmọbìnrin Sioni.

5 Olúwa dàbí ̀;

ó gbé Israẹli .

Ó ti gbé gbogbo ààfin rẹ̀

ó pa ibi gíga rẹ̀ run.

Ó sọ ìmí ̀dùn àti ìbànújẹ́ di púpọ̀

fún àwọn ọmọbìnrin Juda.

6 Ó ìparun ibi mímọ́,

ó pa ibi ìpàdé rẹ̀ run.

Olúwa ti Sioni gbàgbé

àjọ̀dún a yàn àti ̀sẹ̀ ó yàn;

nínú ìbínú gbígbóná rẹ̀ ni ó run

ọba àti olórí àlùfáà.

7 Olúwa ti kọ̀ pẹpẹ rẹ̀ sílẹ̀

ó ti kọ̀ ibi mímọ́ rẹ̀.

Ó fi ̀lọ́wọ́

àwọn odi ààfin rẹ̀;

wọ́n kígbe ilé Olúwa

gẹ́gẹ́ ọjọ́ àpèjẹ a yàn.

8 Olúwa pinnu láti fa

ògiri ó ọmọbìnrin Sioni ya.

Ó gbé wọn sórí òsùwọ̀n,

fa ọwọ́ rẹ̀ padà kúrò nínú ìparun wọn.

Ó ilé ìṣọ́ àti odi rẹ̀ ṣọ̀fọ̀

wọ́n ṣòfò papọ̀.

9 Ẹnu-ọ̀rẹ̀ ti wọ inú ilẹ̀;

òpó rẹ̀ ni ó ó ti bàjẹ́.

Ọba àti ọmọ ọbakùnrin rẹ̀ ìgbèkùn láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,

òfin mọ́,

àwọn wòlíì rẹ̀

ìran láti ̀dọ̀ Olúwa mọ́.

10 Àwọn àgbàgbà ọmọbìnrin Sioni

jókòó sílẹ̀ ìdákẹ́rọ́rọ́;

wọ́n da eruku orí wọn

wọ́n wọ aṣọ àkísà.

Àwọn ̀dọ́mọbìnrin Jerusalẹmu

ti tẹrí wọn ba ilẹ̀.

11 Ojú mi kọ̀ láti sọkún,

mo ń jẹ ìrora nínú mi,

mo ọkàn mi jáde ilẹ̀

nítorí a pa àwọn ènìyàn run,

nítorí àwọn ọmọdé àti ọmọ ọwọ́ ń

òpópó ìlú.

12 Wọ́n fún àwọn ìyá wọn,

"Níbo ni ọkà àti wáìnì ?" ó

wọ́n ṣe ń lọ àwọn ọkùnrin a ṣe léṣe

àwọn òpópónà ìlú,

ayé wọn ṣe ń ṣòfò

láti ọwọ́ ìyá wọn.

13 ni mo le sọ fún ?

Pẹ̀ni mo fi ́ ,

ìwọ ọmọbìnrin Jerusalẹmu?

ni mo fi ́ ,

n ́ nínú,

ìwọ wúńdíá obìnrin Sioni?

Ọgbẹ́ rẹ Òkun.

Ta ni yóò ́ sàn?

14 Ìran àwọn wòlíì rẹ

jẹ́ kìkì ̀tàn láìní ìwọ̀n;

wọn fi ̀ṣẹ̀ rẹ̀ hàn

yóò ìgbèkùn kúrò fún .

Àwọn òrìṣà wọ́n fún

jẹ́ èké àti ìmúniṣìnà.

15 Àwọn ó gba ̀̀dọ̀ rẹ

pàtẹ́wọ́ lórí;

wọ́n kẹ́gàn wọ́n ju orí wọn

ọmọbìnrin Jerusalẹmu:

"Èyí ha ni ìlú à ń

àṣepé ẹwà,

ìdùnnú gbogbo ayé?"

16 Gbogbo àwọn ̀rẹ la ẹnu wọn

gbòòrò ;

wọ́n kẹ́gàn, wọ́n payínkeke

wọ́n , "A ti gbé e tán.

Èyí ni ọjọ́ a ti ń retí;

a láti ."

17 Olúwa ti ṣe ohun ó pinnu;

ó ti ̀rọ̀ rẹ̀ ṣẹ,

ó pàṣẹ ọjọ́ pípẹ́.

Ó ti ṣí ipò láì láàánú,

ó fún ̀ìṣẹ́gun lórí rẹ,

ó ti gbé ìwo àwọn ̀rẹ̀ ga.

18 Ọkàn àwọn ènìyàn

kígbe jáde Olúwa.

Odi ọmọbìnrin Sioni,

jẹ́ ẹkún rẹ̀ sàn odò

̀sán àti òru;

ṣe fi ara rẹ fún ìtura,

ojú rẹ fún ìsinmi.

19 Dìde, kígbe sókè àṣálẹ́,

ìṣọ́ òru ti bẹ̀rẹ̀

ọkàn rẹ̀ jáde omi

níwájú Olúwa.

Gbé ọwọ́ yín sókè i

nítorí ̀àwọn èwe rẹ̀

ó ń lọ nítorí ebi

gbogbo oríta òpópó.

20 "ó, Olúwa, o ó.

Ta ni ìwọ ti fìyà jẹ èyí.

Ǹjẹ́ àwọn obìnrin yóò ha jẹ ọmọ wọn,

àwọn ọmọ wọn ń ṣe ìtọ́fún?

Ǹjẹ́ a pa olórí àlùfáà àti àwọn wòlíì

ibi mímọ́ Olúwa?

21 "Ọmọdé àti àgbà ń sùn papọ̀

sínú eruku àwọn òpópó;

àwọn ̀dọ́mọkùnrin àti ̀dọ́mọbìnrin mi

ti ṣègbé nípa idà.

Ìwọ pa wọ́n run ọjọ́ ìbínú rẹ,

Ìwọ pa wọ́n láìní àánú.

22 "ó ti ṣe ọjọ́ àsè,

bẹ́̀ ni ó ṣe fi ̀̀gbẹ́ mi.

ọjọ́ ìbínú Olúwa

ẹni ó sálà ó ;

àwọn mo ti tọ́mo fẹ́ràn,

ni ̀mi parun."

Veja também

Publicidade
Lamentações
Ver todos os capítulos de Lamentações
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-