Publicidade

Lamentações 5

1 Rántí, Olúwa, ohun ó ṣẹlẹ̀ wa;

ó, o ìtìjú wa.

2 Àwọn ohun ìní wa ti di ti àlejò,

ilé wa ti di ti àjèjì.

3 Àwa ti di aláìní òbí àti aláìní baba,

àwọn ìyá wa ti di opó.

4 A gbọdọ̀ ra omi à ń mu;

igi wa di títà fún wa.

5 Àwọn ó ń wa súnmọ́ wa;

àárẹ̀ wa àwa ìsinmi.

6 Àwa jọ̀wọ́ ara wa fún Ejibiti àti Asiria

láti oúnjẹ jẹ.

7 Àwọn baba wa ti ṣẹ̀, wọn ṣí mọ́,

àwa ń ru ìjìyà ̀ṣẹ̀ wọn.

8 Àwọn ẹrú ń jẹ ọba lórí wa,

ṣí ẹni yóò gbà lọ́wọ́ wọn.

9 Àwa ń oúnjẹ wa nínú ewu ̀wa

nítorí idà ó aginjù.

10 Ẹran-ara wa gbóná ààrò,

ebi wa àárẹ̀.

11 Wọ́n ti fipá àwọn obìnrin wa lòpọ̀ Sioni,

àti àwọn wúńdíá ti o wa ìlú Juda.

12 Àwọn ọmọ ọbakùnrin ti di síso sókè ọwọ́ wọn;

ìbọ̀wọ̀ fún àgbàgbà mọ́.

13 Àwọn ̀dọ́mọkùnrin wa ru òkúta;

àwọn ọmọkùnrin ń ṣàárẹ̀ lábẹ́ ẹrù igi.

14 Àwọn àgbàgbà ti lọ kúrò ẹnu-bodè ìlú;

àwọn ̀dọ́mọkùnrin dákẹ́ orin wọn.

15 Ayọ̀ ti ṣáko ọkàn wa;

̀fọ̀ ti dúró ijó fún wa.

16 Adé ti ṣí kúrò orí wa

ègbé ni fún wa, nítorí a ti ṣẹ̀.

17 Nítorí èyí, àárẹ̀ ọkàn wa,

nítorí èyí, ojú wa ṣú.

18 Fún òkè Sioni ó ti di ahoro

lórí rẹ̀ àwọn kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ ń rìn kiri.

19 Ìwọ, Olúwa, jẹ ọba títí láé;

ìjọba rẹ dúró láti ìran kan ìran mìíràn.

20 o ń gbàgbé wa gbogbo ìgbà?

o fi kọ̀ sílẹ̀ fún ọjọ́ pípẹ́?

21 wa padà ̀dọ̀ rẹ, Olúwa, àwa ó le padà;

ọjọ́ wa di tuntun ìgbàanì,

22 àyàfi o ti kọ̀ sílẹ̀ pátápátá

ìbínú rẹ wa kọjá ìwọ̀n.

Veja também

Lamentações
Ver todos os capítulos de Lamentações
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-