Publicidade

Mateus 6

Ìtọrẹ àánú

1 "kíyèsára ṣe iṣẹ́ rere yín níwájú àwọn ènìyàn nítorí a le yín, ṣe bẹ́̀, ̀yin ni èrè kankan lọ́dọ̀ Baba yín ̀run.

2 "Nítorí náà, nígbà ti ́ ti ń fún aláìní, ṣe fi fèrè kéde rẹ̀, gẹ́gẹ́ àwọn àgàbàgebè ti í ṣe Sinagọgu àti ìta gbangba; àwọn ènìyàn le yìn wọ́n. Lóòótọ́ ni mo fún yín, wọ́n ti gba èrè wọn kíkún. 3 Ṣùgbọ́n ìwọ ń fi fún aláìní, ṣe jẹ́ ọwọ́ òsì rẹ mọ ohun ọwọ́ ̀tún rẹ ń ṣe, 4 ìfúnni rẹ ṣe jẹ́ mọ̀. Nígbà náà ni Baba rẹ̀, ó mọ ohun ìkọ̀kọ̀ gbogbo, yóò san án fún .

Àdúrà

5 "Nígbà ìwọ ń gbàdúrà, ṣe ṣe àwọn àgàbàgebè, nítorí wọn fẹ́ràn láti máa dúró gbàdúrà Sinagọgu àti ̀gbẹ́ ̀ènìyàn ti wọ́n. Lóòótọ́ ni mo fún yín, wọ́n ti gba èrè wọn kíkún. 6 Ṣùgbọ́n nígbà ìwọ ń gbàdúrà, wọ inú iyàrá rẹ lọ, ìlẹ̀kùn mọ́ ara rẹ, gbàdúrà Baba rẹ ẹni ìwọ . Nígbà náà ni Baba rẹ ó mọ gbogbo ohun ìkọ̀kọ̀ rẹ, yóò san án fún . 7 Ṣùgbọ́n nígbà ti ̀yin ń gbàdúrà, ṣe àtúnwí asán àwọn aláìkọlà, nítorí wọn a ó tìtorí ̀pọ̀ ̀rọ̀ gbọ́ tiwọn. 8 ṣe dàbí i wọn, nítorí Baba yín ń bẹ ̀run mọ ohun ṣe aláìní, tilẹ̀ béèrè lọ́wọ́ rẹ̀.

9 "Nítorí náà, báyìí ni ṣe máa gbàdúrà:

" Baba wa ń bẹ ̀run,

̀wọ̀ fún orúkọ yín,

10 ìjọba yín ,

ìfẹ́ tiyín ni a ṣe

ayé ti ̀run.

11 fún wa oúnjẹ òòjọ́ wa lónìí.

12 dárí gbèsè wa ,

àwa ti ń dáríji àwọn ajigbèsè wa,

13 ṣe sínú ìdánwò,

ṣùgbọ́n gbà lọ́wọ́ ibi.

Nítorí ìjọba ni tiyín, àti agbára àti ògo, láéláé, Àmín.

14 Nítorí náà, ̀yin dárí àwọn ṣẹ̀ yín, baba yín ̀run náà yóò dáríjì yín. 15 Ṣùgbọ́n ̀yin kọ̀ láti dárí ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn wọ́n, baba yín í dárí ̀ṣẹ̀ yín yín.

Àwẹ̀

16 "Nígbà ̀yin gbààwẹ̀, ṣe fa ojú ro àwọn àgàbàgebè ṣe máa ń ṣe nítorí wọn máa ń fa ojú ro láti fihàn àwọn ènìyàn àwọn ń gbààwẹ̀. Lóòótọ́ ni mo fún yín wọn ti gba èrè wọn kíkún. 17 Ṣùgbọ́n nígbà ìwọ gbààwẹ̀, bu òróró orí rẹ, ó tún ojú rẹ ṣe dáradára. 18 ó ṣe hàn ènìyàn ìwọ ń gbààwẹ̀, ṣe í Baba rẹ, ẹni ìwọ , àti , Baba rẹ ó ohun o ṣe ni ìkọ̀kọ̀, yóò san án fún .

Títo ìṣúra jọ ̀run

19 "ṣe to àwọn ìṣúra jọ fún ara rẹ ayé yìí, níbi kòkòrò ti le jẹ ́, ó ti le bàjẹ́ àti ibi àwọn olè fọ́ wọ́n yóò i lọ. 20 Dípò bẹ́̀ to ìṣúra rẹ jọ ̀run, níbi ti kòkòrò àti ìpáàrà ti á jẹ́, àti ibi àwọn olè le fọ́ wọlé láti í lọ. 21 Nítorí ibi ìṣúra yín níbẹ̀ náà ni ọkàn yín yóò pẹ̀.

22 "Ojú ni fìtílà ara. ojú rẹ mọ́lẹ̀ kedere, gbogbo ara rẹ yóò jẹ́ kìkì ìmọ́lẹ̀. 23 Ṣùgbọ́n ojú rẹ dára, gbogbo ara rẹ ni yóò kún fún òkùnkùn. ìmọ́lẹ̀ ti ó nínú rẹ jẹ́ òkùnkùn, òkùnkùn náà yóò ti pọ̀ !

24 "í ẹnìkan ó sin ̀méjì. Òun yóò kórìíra ̀kan yóò fẹ́ràn èkejì, tàbí ó fi ara mọ́ ̀kan ó yan èkejì ìpọ̀. ̀yin sin Ọlọ́run àti owó papọ̀.

ṣe àníyàn

25 "Nítorí náà, mo fún yín, ṣe ṣe àníyàn nípa ̀yín, ohun ó jẹ àti èyí ó mu; tàbí nípa ara yín, ohun ó wọ̀. Ṣé ̀ha ṣe pàtàkì ju oúnjẹ lọ tàbí ara ni ha ṣe pàtàkì ju aṣọ lọ? 26 wo àwọn ẹyẹ ojú ọrun; wọn í gbìn, bẹ́̀ ni wọn í kórè, bẹ́̀ ni wọn í kójọ sínú àká, síbẹ̀ Baba yín ń bẹ ̀run ń bọ́ wọn. ̀yin ha níye lórí wọ́n lọ ? 27 Ta ni nínú gbogbo yín nípa àníyàn ṣíṣe ti ó fi ìṣẹ́kan kún ọjọ́ ayé rẹ̀?

28 "ni ìdí ti fi ń ṣe àníyàn ti aṣọ? wo àwọn lílì ń bẹ igbó ti ń dàgbà. Wọn í ṣiṣẹ́ bẹ́̀ ni wọn í rànwú. 29 Bẹ́̀ ni mo fún yín , a ṣe Solomoni lọ́ṣọ̀́ nínú gbogbo ògo rẹ̀ ̀kan nínú àwọn nǹkan wọ̀nyí. 30 Ǹjẹ́ Ọlọ́run wọ koríko igbó aṣọ bẹ́̀, èyí ó níhìn-ín lónìí ti a gbà sínú iná lọ́la, ha ṣe ni ṣe yín lọ́ṣọ̀́ bẹ́̀ àti bẹ́̀ lọ, ̀yin ìgbàgbọ́ yín kéré? 31 Nítorí náà, ṣe ṣe àníyàn máa , ni àwa yóò jẹ?tàbí ni àwa yóò mu?tàbí Irú aṣọ wo ni àwa yóò wọ̀?’ 32 Nítorí àwọn kèfèrí ń fi ìwọra àwọn nǹkan wọ̀nyí bẹ́̀ ni Baba yín ̀run mọ̀ dájúdájú ìlò àwọn nǹkan wọ̀nyí. 33 Ṣùgbọ́n, kọ́kọ́ ìjọba Ọlọ́run àti òdodo rẹ̀, yóò fi gbogbo àwọn nǹkan wọ̀nyí kún un fún yín pẹ̀. 34 Nítorí náà, ṣe àníyàn ̀la, ̀la ni yóò ṣe àníyàn ara rẹ̀. Wàhálà ọjọ́ kọ̀̀kan ti fún un.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-