Publicidade

Agradecimento a Deus

Por Bíblia Online

Agradecer a Deus é louvor, adoração e reconhecimento da sua soberania. Dai graças ao Senhor porque Ele é bom — a sua misericórdia dura para sempre!

jẹ́ a iwájú rẹ̀ pẹ̀ọpẹ́

a pòkìkí rẹ̀ pẹ̀ohun èlò

orin àti ìyìn.

lọ ẹnu-ọ̀rẹ̀ pẹ̀ọpẹ́

àti àgbàlá rẹ̀ pẹ̀ìyìn;

fi ọpẹ́ àti ìyìn fún orúkọ rẹ̀.

Yin Olúwa! fi ìyìn fún

Olúwa, nítorí ó ṣeun.

fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí ó ṣeun,

nítorí ìfẹ́ rẹ̀ dúró láéláé.

Ìwọ ni Ọlọ́run mi, èmi yóò máa fi ọpẹ́ fún ;

ìwọ ni Ọlọ́run mi, èmi yóò gbé ga.

Fi ọpẹ́ kọrin Olúwa

fi ohun èlò orin olókùn yin Ọlọ́run.

Èmi yóò fi orin gbé orúkọ Ọlọ́run ga

èmi yóò fi ọpẹ́ gbé orúkọ rẹ̀ ga.

Olúwa ni agbára mi àti asà mi;

nínú rẹ̀ ni mo gbẹ́kẹ̀; àní, ó ràn lọ́wọ́.

Ọkàn mi gbé sókè fún ayọ̀

àní pẹ̀orin mi mo fi ọpẹ́ fún un.

Nísinsin yìí, Ọlọ́run wa, àwa fi ọpẹ́ fún ,

a fi ìyìn fún orúkọ rẹ̀ ó lógo.

ṣe ṣe àníyàn ohunkóhun; ṣùgbọ́n nínú ohun gbogbo, nípa àdúrà àti ̀bẹ̀ pẹ̀ìdúpẹ́, máa fi ìbéèrè yín hàn fún Ọlọ́run.

Ìdúpẹ́ àti àdúrà

Mo ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run mi gbogbo ìgbà mo rántí yín.

Ohunkóhun ̀yin ń ṣe ̀rọ̀ tàbí ìṣe, máa ṣe gbogbo wọn orúkọ Jesu Olúwa, máa fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run Baba nípasẹ̀ rẹ̀.

Ọpẹ́ fún ìgbàgbọ́ àwọn ará Tẹsalonika

Gbogbo ìgbà ni a máa ń fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run nítorí yín, a ń gbàdúrà fún un yín nígbà gbogbo pẹ̀. A ń rántí yin ni àìsimi nígbà gbogbo níwájú Ọlọ́run àti Baba nípa iṣẹ́ ìgbàgbọ́ yín, iṣẹ́ ìfẹ́ yín àti ìdúró ṣinṣin ìrètí yín nínú Jesu Kristi Olúwa wa.

Ìdúpẹ́

Nígbà gbogbo ni mo ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run fún oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ fi fún un yín nínú Kristi Jesu.

Ṣùgbọ́n ọpẹ́ fún Ọlọ́run ẹni ó ìṣẹ́gun fún nípa Olúwa Jesu Kristi!

Ṣùgbọ́n ọpẹ́ ni fún Ọlọ́run, ẹni ń yọ ayọ̀ ìṣẹ́gun lórí nígbà gbogbo nínú Kristi, a ń fi òórùn dídùn ìmọ̀ rẹ̀ hàn nípa wa níbi gbogbo.

Ǹjẹ́ ẹni ń fi irúgbìn fún afúnrúgbìn, àti àkàrà fún oúnjẹ, yóò fi irúgbìn fún un yín, yóò sọ ́ di púpọ̀, yóò èso òdodo yín i. Bẹ́̀ ni a ó sọ yín di ọlọ́rọ̀ nínú ohun gbogbo, fún ìlawọ́ yín gbogbo ń ṣiṣẹ́ ọpẹ́ Ọlọ́run nípa wa.

máa ara yín sọ̀rọ̀ nínú Saamu, àti orin ìyìn, àti orin ̀, máa kọrin, máa kọrin dídùn ọkàn yín Olúwa. máa dúpẹ́ nígbà gbogbo fún ohun gbogbo lọ́wọ́ Ọlọ́run, àní Baba, orúkọ Jesu Kristi Olúwa .

Àwọn aya àti ọkọ

máa tẹríba fún ara yín ìbẹ̀Ọlọ́run.

Nígbà ó ìṣù àkàrà márùn-ún àti ẹja méjì náà, ó gbé ojú rẹ̀ sókè ̀run. Ó dúpẹ́ fún oúnjẹ náà, ó wọ́n wẹ́wẹ́, ó fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ láti gbé e kalẹ̀ síwájú àwọn ènìyàn náà àti àwọn ẹja méjì náà ni ó pín fún gbogbo wọn. Gbogbo wọn jẹ àjẹyó. Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn agbọ̀n méjìlá ó kún fún àjẹkù àkàrà àti ti ẹja pẹ̀.

Seja o primeiro
Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-