Publicidade

Salmos 95

1 , jẹ́ a kọ orin ayọ̀ Olúwa,

jẹ́ a kígbe sókè àpáta ìgbàlà wa.

2 jẹ́ a iwájú rẹ̀ pẹ̀ọpẹ́

a pòkìkí rẹ̀ pẹ̀ohun èlò

orin àti ìyìn.

3 Nítorí Olúwa Ọlọ́run títóbi ni,

ọba ó tóbi ju gbogbo òrìṣà lọ.

4 ọwọ́ rẹ̀ ni ̀gbun ilẹ̀ ,

ṣóńṣó orí òkè tirẹ̀ ṣe.

5 Tirẹ̀ ni Òkun, nítorí òun ni ó a

àti ọwọ́ rẹ̀ ni ó fi ìyàngbẹ ilẹ̀.

6 , jẹ́ a foríbalẹ̀ a sìn ín,

jẹ́ a kúnlẹ̀ níwájú

Olúwa ẹni ó wa,

7 nítorí òun ni Ọlọ́run wa,

àwa ni ènìyàn pápá rẹ̀,

àti ̀wọ́ ẹran ni abẹ́ ìpamọ́ rẹ̀.

Lónìí ìwọ gbọ́ ohùn rẹ̀,

8 "ṣe ọkàn yín le gẹ́gẹ́ ti ṣe Meriba,

àti ti ṣe ọjọ́ náà Massa aginjù,

9 nígbà àwọn baba yín dán mi

wọn wádìí mi,

wọn iṣẹ́ mi.

10 Fún ogójì ọdún ni èmi fi bínú ìran náà;

mo , Wọ́n jẹ́ ènìyàn ọkàn wọn ṣáko lọ

wọn mọ ̀mi.

11 Nítorí náà ni mo kéde ìbúra nínú ìbínú mi,

Wọn yóò wọ ibi ìsinmi mi.’ "

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-