Publicidade

1 Crônicas 29

̀bùn fún kíkọ́ ilé Olúwa

1 Nígbà náà, ọba Dafidi sọ fún gbogbo àpéjọ , "Ọmọ mi Solomoni, èyí Ọlọ́run ti yàn, kéré ó jẹ́ aláìmòye. Iṣẹ́ náà tóbi, nítorí ìkọ́ti ààfin í ṣe fún ènìyàn ṣùgbọ́n fún Olúwa Ọlọ́run. 2 Pẹ̀gbogbo ìrànlọ́wọ́ mi èmi ti pèsè fún ilé Ọlọ́run mi wúrà fún iṣẹ́ wúrà, fàdákà fún ti fàdákà, idẹ fún ti idẹ, irin fún ti irin àti igi fún ti igi àti òkúta oníyebíye fún títọ́ rẹ̀, òkúta lóríṣìíríṣìí, àwọ̀ àti oríṣìíríṣìí ̀òkúta àti òkúta dáradára kan gbogbo wọ̀nyí iye púpọ̀. 3 Yàtọ̀ fún èyí, nínú ìfọkànsìn mi ilé Ọlọ́run mi, èmí fi ìṣúra mi tìkára mi ti wúrà àti fàdákà fún ilé Ọlọ́run mi. gbogbo rẹ̀ lọ, èmi ti pèsè fún ilé mímọ́ ti Olúwa yìí, 4 ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000) tálẹ́ǹtì wúrà, ti wúrà Ofiri àti ̀́dẹ́gbàárin (7,000) tálẹ́ǹtì fàdákà dídára, fún bíbo àwọn ògiri ilé náà. 5 Fún iṣẹ́ wúrà àti fàdákà náà, àti fún oríṣìí iṣẹ́ ti ó yẹ ṣíṣe nípasẹ̀ àwọn ó òye oríṣìíríṣìí iṣẹ́. Nísinsin yìí, ta ni ó ìfẹ́ yíya ará rẹ̀ sọ́tọ̀ lónìí Olúwa?"

6 Nígbà náà àwọn aṣáájú àwọn ìdílé, àwọn ìjòyè àwọn ̀Israẹli, àwọn alákòóso ẹgbẹgbẹ̀wàá àti alákòóso ̀rọ̀̀rún àti àwọn oníṣẹ́ ó ìdí iṣẹ́ ọba ìfẹ́ i. 7 Wọ́n fi sílẹ̀ fún iṣẹ́ lórí ilé Ọlọ́run, ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) tálẹ́ǹtì àti ẹgbẹ̀rin mẹ́wàá (10,000) wúrà, ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) tálẹ́ǹtì fàdákà, ẹgbàá mẹ́sàn (18,000) tálẹ́ǹtì idẹ àti ọgọ́rin ẹgbẹ̀rin (100,000) tálẹ́ǹtì irin. 8 Ẹnikẹ́ni ó òkúta iyebíye fi wọn ilé ìṣúra ilé Olúwa abẹ́ ìtọ́Jehieli ará Gerṣoni. 9 Àwọn ènìyàn láyọ̀ nínú ìṣesí àtọkànwá fi sílẹ̀ àwọn olórí wọn, nítorí wọ́n ti fi sílẹ̀ ̀fẹ́ pẹ̀gbogbo ọkàn Olúwa. Dafidi ọba pẹ̀yọ̀ gidigidi.

Àdúrà Dafidi

10 Dafidi yin Olúwa níwájú gbogbo àwọn ó péjọ, ,

"Ìyìn ni fún , Olúwa,

Ọlọ́run baba a wa Israẹli,

láé àti láéláé.

11 Tìrẹ Olúwa ni títóbi àti agbára pẹ̀ìyìn

àti ọláńlá àti dídán,

nítorí gbogbo nǹkan ̀run àti ayé jẹ́ tìrẹ.

Tìrẹ Olúwa ni ìjọba;

a gbé ga gẹ́gẹ́ orí lórí ohun gbogbo.

12 Ọlá àti ̀wọ̀ láti ̀dọ̀ Rẹ;

ìwọ ni alákòóso gbogbo nǹkan.

ọwọ́ rẹ ni ipá àti agbára láti gbéga àti

láti fi agbára fún ohun gbogbo.

13 Nísinsin yìí, Ọlọ́run wa, àwa fi ọpẹ́ fún ,

a fi ìyìn fún orúkọ rẹ̀ ó lógo.

14 "Ṣùgbọ́n ta ni èmi, àti ta ni àwọn ènìyàn mi, a fi ṣe ìrànlọ́wọ́ tinútinú irú èyí? Gbogbo nǹkan láti ̀dọ̀ rẹ ti , àwa ti fífún láti ara ohun ó láti ọwọ́ rẹ. 15 Àwa jẹ́ àjèjì àti àlejò ojú rẹ gẹ́gẹ́ baba ńlá a wa, àwọn ọjọ́ wa lórí ilẹ̀ ayé òjìji láìsí ìrètí. 16 Olúwa Ọlọ́run wa fi gbogbo púpọ̀ yìí àwa ti pèsè fún kíkọ́ ilé Olúwa fun orúkọ, mímọ́ rẹ̀, ó láti ọwọ́ ̀ rẹ, gbogbo rẹ̀ jẹ́ tirẹ̀. 17 Èmi mọ̀ Ọlọ́run mi, ìwọ̀ dán ọkàn , ó tẹ́ lọ́rùn pẹ̀òtítọ́ inú. Gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni èmi ti fi sílẹ̀ pẹ̀tìfẹ́tìfẹ́ pẹ̀òtítọ́. Nísinsin yìí èmi ti i pẹ̀ayọ̀ àwọn ènìyàn yìí ó níbí ti fi fún pẹ̀tìfẹ́tìfẹ́. 18 Olúwa Ọlọ́run àwọn baba a wa Abrahamu, Isaaki àti Israẹli pa ìfẹ́ yìí mọ́ nínú ọkàn àwọn ènìyàn rẹ títí láé pẹ̀pípa ọkàn mọ́ lóòtítọ́ . 19 Àti fún ọmọ mi Solomoni ìfọkànsìn tòótọ́ láti pa àṣẹ rẹ mọ́ àwọn ohun ó nílò àti òfin àti láti ṣe ohun gbogbo láti kọ́ ààfin ti ọba fún èyí mo ti pèsè."

20 Dafidi sọ fún gbogbo ìjọ ènìyàn , "Nísinsin yìí, fi ìyìn fún Olúwa Ọlọ́run yín." Gbogbo ènìyàn fi ìyìn fún Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn, wọ́n tẹ orí wọn ba, wọ́n wólẹ̀ fún Olúwa àti ọba.

A yan Solomoni gẹ́gẹ́ ọba

21 Ni ọjọ́ kejì, wọ́n ẹbọ Olúwa, wọ́n ẹbọ sísun i: ẹgbẹ̀rún (1,000) kan akọ màlúù, ẹgbẹ̀rin (1,000) kan àgbò, àti ẹgbẹ̀rin kan akọ ̀dọ́-àgùntàn. Lápapọ̀ pẹ̀ọrẹ mímu àti àwọn ẹbọ mìíràn ̀pọ̀lọpọ̀ fún gbogbo Israẹli. 22 Wọ́n jẹ wọ́n mu pẹ̀ayọ̀ kíkún iwájú Olúwa ọjọ́ náà.

Nígbà náà wọ́n yan Solomoni ọmọ Dafidi gẹ́gẹ́ ọba lẹ́̀kejì wọ́n fi àmì òróró yàn án níwájú Olúwa láti ṣe olórí àti Sadoku láti ṣe àlùfáà. 23 Bẹ́̀ ni Solomoni jókòó lórí ìtẹ́ Olúwa gẹ́gẹ́ ọba ipò baba a rẹ̀ Dafidi. O ṣe àṣeyọrí, gbogbo Israẹli gbọ́rọ̀ i lẹ́nu. 24 Gbogbo àwọn ìjòyè àti àwọn ọkùnrin alágbára, pẹ̀gbogbo àwọn ọmọ ọba Dafidi tẹrí ara wọn ba fún ọba Solomoni.

25 Olúwa gbé Solomoni ga púpọ̀ ojú gbogbo Israẹli, ó kẹ́ ìkẹ́ ọláńlá, irú èyí a kẹ́ ọba kankan ṣáájú rẹ̀ ó jẹ lórí Israẹli.

Ikú Dafidi

26 Dafidi ọmọ Jese jẹ́ ọba lórí gbogbo Israẹli. 27 Ó jẹ ọba lórí Israẹli fún ogójì ọdún; ọdún méje ni ó jẹ ọba Hebroni, ó jẹ ọba ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n Jerusalẹmu. 28 Òun darúgbó, ó ikú rere, ó gbádùn ̀gígùn, ọlá àti ọrọ̀. Solomoni ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

29 ti ohun ó ṣẹlẹ̀ nígbà ìjọba ọba Dafidi, láti ìbẹ̀rẹ̀ òpin, a kọ wọ́n sínú ìwé ìrántí ti Samuẹli aríran, ìwé ìrántí ti Natani wòlíì àti ìwé ìrántí ti Gadi aríran, 30 lápapọ̀, pẹ̀gbogbo ìjọba àti agbára rẹ̀ pẹ̀àwọn ìgbà ó kọjá lórí rẹ̀, àti lórí Israẹli, àti lórí gbogbo àwọn ìjọba gbogbo ilẹ̀ náà.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-