Publicidade

Alegria e felicidade

Por Bíblia Online

A alegria é fruto do Espírito e marca do cristão. Alegrai-vos sempre no Senhor! A Bíblia ensina que a alegria de Deus é nossa fortaleza — não depende de circunstâncias, mas da presença de Deus.

Alegrai-vos no Senhor

Alegrai-vos sempre no Senhor! Outra vez digo: alegrai-vos! Na presença de Deus há plenitude de alegria eterna.

máa yọ̀ nínú Olúwa nígbà gbogbo: mo tún . máa yọ̀.

máa yọ̀ nínú Olúwa nígbà gbogbo: mo tún . máa yọ̀.

Ìwọ ti fi ipa ̀ìyè hàn ;

Ìwọ yóò kún mi pẹ̀ayọ̀ iwájú rẹ,

pẹ̀ìdùnnú ayérayé ọwọ́ ̀tún rẹ.

Ìwọ ti fi ipa ̀ìyè hàn ;

Ìwọ yóò kún mi pẹ̀ayọ̀ iwájú rẹ,

pẹ̀ìdùnnú ayérayé ọwọ́ ̀tún rẹ.

Mo ti gbé Olúwa síwájú mi ìgbà gbogbo.

Nítorí ó ọwọ́ ̀tún mi, a yóò .

Nítorí èyí, ọkàn mi yọ̀, ahọ́n mi pẹ̀ń fáyọ̀;

ara mi pẹ̀yóò sinmi ààbò,

Ṣùgbọ́n, jẹ́ gbogbo àwọn ó sádi ́ ó yọ̀;

jẹ wọn máa kọrin fún ayọ̀ títí.

Tan ààbò rẹ sórí wọn,

àti àwọn ó fẹ́ràn orúkọ rẹ yóò máa yọ̀ nínú rẹ.

Ìwọ ni ibi ìpamọ́ mi;

ìwọ yóò pa mọ́ kúrò nínú ìyọnu;

ìwọ yóò fi orin ìgbàlà mi ka. Sela.

pàtẹ́wọ́, gbogbo ̀yin ènìyàn

Ọlọ́run pẹ̀orin ayọ̀ rinlẹ̀.

Nítorí Olúwa inú dídùn àwọn ènìyàn rẹ̀

ó fi ìgbàlà àwọn onírẹ̀lẹ̀ ládé.

Fruto do Espírito

O fruto do Espírito é amor, alegria, paz. A alegria do Senhor é nossa fortaleza — não depende do mundo.

Ṣùgbọ́n èso ti ̀ni ìfẹ́, ayọ̀, àlàáfíà, ìpamọ́ra, ìwà pẹ̀lẹ́, ìṣoore, ìgbàgbọ́, ìwà tútù, àti ìkóra-ẹni níjanu, òfin kan lòdì irú wọ̀nyí,

Nehemiah , "lọ gbádùn oúnjẹ yàn láàyò ohun dídùn, díẹ̀ ránṣẹ́ àwọn . Ọjọ́ yìí, mímọ́ ni fún Olúwa wa. ṣe banújẹ́, nítorí ayọ̀ Olúwa ni agbára yín."

Nehemiah , "lọ gbádùn oúnjẹ yàn láàyò ohun dídùn, díẹ̀ ránṣẹ́ àwọn . Ọjọ́ yìí, mímọ́ ni fún Olúwa wa. ṣe banújẹ́, nítorí ayọ̀ Olúwa ni agbára yín."

Èyí ni ọjọ́ Olúwa :

jẹ́ ayọ̀ inú wa máa dùn nínú rẹ̀.

Èmi ń yọ̀ ̀̀rẹ,

ènìyàn ṣe ń yọ̀ nínú ọláńlá.

Òfin rẹ ni ogún mi láéláé;

àwọn ni ayọ̀ ọkàn mi.

Ìbùkún ni fún gbogbo ẹni ó bẹ̀Olúwa:

ó ń rìn ̀rẹ̀.

Nítorí ìwọ yóò jẹ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ

ìbùkún ni fún ; yóò dára fún .

Alegria nas tribulações

Os que semeiam em lágrimas ceifarão com alegria. Tende por motivo de grande gozo quando caídes em diversas tentações.

Àwọn ń fi omijé fún irúgbìn

yóò fi ayọ̀ ka.

Nítorí ìbínú rẹ̀ fún ìgbà díẹ̀,

ojúrere rẹ̀ títí ayérayé;

ẹkún pẹ́ títí di alẹ́,

ṣùgbọ́n ayọ̀ yóò òwúrọ̀.

Nítorí ìbínú rẹ̀ fún ìgbà díẹ̀,

ojúrere rẹ̀ títí ayérayé;

ẹkún pẹ́ títí di alẹ́,

ṣùgbọ́n ayọ̀ yóò òwúrọ̀.

Àwọn ìṣòro àti àwọn ìdánwò

̀yin ará mi, nígbà ̀yin bọ́ sínú onírúurú ìdánwò, ka gbogbo rẹ̀ ayọ̀; nítorí ̀yin mọ̀ , ìdánwò ìgbàgbọ́ yín ń ṣiṣẹ́ sùúrù.

igi ̀pọ̀tọ́ ko tilẹ̀ tanná,

èso nínú àjàrà;

igi olifi ko le so,

àwọn oko ko oúnjẹ ;

a agbo ẹran kúrò nínú agbo,

ọwọ́ ẹran ni ibùso mọ́,

síbẹ̀, èmi ó láyọ̀ nínú Olúwa,

èmi yóò máa yọ nínú Ọlọ́run ìgbàlà mi.

Nítorí náà èmi inú dídùn nínú àìlera gbogbo, nínú ̀gàn gbogbo, nínú àìní gbogbo, nínú inúnibíni gbogbo, nínú wàhálà gbogbo nítorí Kristi. Nítorí nígbà mo jẹ́ aláìlera, nígbà náà ni mo di alágbára.

Ẹni ̀yin fẹ́ láìrí, ẹni ̀yin gbàgbọ́, ó tilẹ̀ jẹ́ i nísinsin yìí ̀yin ń yọ ayọ̀ a fi ẹnu sọ, ó kún fún ògo; ẹyin ń gba ìlépa ìgbàgbọ́ yín, àní ìgbàlà ọkàn yín.

Ẹni ̀yin fẹ́ láìrí, ẹni ̀yin gbàgbọ́, ó tilẹ̀ jẹ́ i nísinsin yìí ̀yin ń yọ ayọ̀ a fi ẹnu sọ, ó kún fún ògo; ẹyin ń gba ìlépa ìgbàgbọ́ yín, àní ìgbàlà ọkàn yín.

Alegria compartilhada

Alegrai-vos com os que se alegram. O Senhor fez coisas grandiosas por nós — alegrai-vos no Senhor e regozijai-vos.

máa yọ̀ ni ìrètí; máa sùúrù nínú ìpọ́njú; máa dúró gbọingbọin nínú àdúrà.

Àwọn ń yọ̀, máa wọn yọ̀, àwọn ń sọkún, máa wọn sọkún.

Nítorí ìjọba ̀run í ṣe jíjẹ àti mímu, ṣe nípa ti òdodo, àlàáfíà àti ayọ̀ nínú ̀Mímọ́,

Nítorí ìjọba ̀run í ṣe jíjẹ àti mímu, ṣe nípa ti òdodo, àlàáfíà àti ayọ̀ nínú ̀Mímọ́,

Ǹjẹ́ Ọlọ́run ìrètí ó fi gbogbo ayọ̀ òun àlàáfíà kún yín ̀yin ti gbà á gbọ́, ̀yin ó pọ̀ ìrètí nípa agbára ̀Mímọ́.

èmi le fi ayọ̀ tọ̀ yín wa, nípa ìfẹ́ Ọlọ́run, àti èmi ìtura pọ̀ pẹ̀yín.

olúkúlùkù ènìyàn ṣe gẹ́gẹ́ ó ti pinnu ọkàn rẹ̀; í ṣe àfi ìkùnsínú ṣe, tàbí ti àìgbọdọ̀ ṣe; nítorí Ọlọ́run fẹ́ onínúdídùn ọlọ́rẹ.

Ṣùgbọ́n ìwà-bí-Ọlọ́run pẹ̀ìtẹ́lọ́rùn èrè ńlá ni.

Kìlọ̀ fún àwọn ó lọ́rọ̀ ayé ìsinsin yìí wọn ma ṣe gbéraga, bẹ́̀ ni wọn ṣe gbẹ́kẹ̀̀rọ̀ àìdánilójú, ṣe Ọlọ́run alààyè, ń fi ohun gbogbo fún wa lọ́pọ̀lọ́pọ̀ láti ;

Jesus e a alegria

A minha alegria esteja em vós e a vossa alegria seja completa. Pedi e recebereis para que a vossa alegria seja plena.

Nǹkan wọ̀nyí ni mo ti sọ fún yín, ayọ̀ mi ó nínú yín, àti ayọ̀ yín ó kún.

Nǹkan wọ̀nyí ni mo ti sọ fún yín, ayọ̀ mi ó nínú yín, àti ayọ̀ yín ó kún.

Nítorí náà ̀yin ìbànújẹ́ nísinsin yìí, ṣùgbọ́n èmi ó tún yín, ọkàn yín yóò yọ̀, ẹni yóò gba ayọ̀ yín lọ́wọ́ yín.

Títí di ìsinsin yìí ì béèrè ohunkóhun orúkọ mi, béèrè, ó gbà, ayọ̀ yín ó kún.

a máa wo Jesu Olùpilẹ̀ṣẹ̀ àti aláṣepé ìgbàgbọ́ wa; ẹni nítorí ayọ̀ a gbé ka iwájú rẹ, o faradà àgbélébùú láìka ìtìjú , ó jókòó lọ́wọ́ ̀tún ìtẹ́ Ọlọ́run.

Ṣùgbọ́n láìsí ìgbàgbọ́ ṣe é ṣe láti ú; nítorí ẹni ó ń tọ Ọlọ́run ṣàì gbàgbọ́ ó ń bẹ, àti òun olùṣẹ̀san fún àwọn o fi ara balẹ̀ a.

Alegria eterna

Alegria eterna terão sobre suas cabeças. O Senhor reinará com alegria sobre o seu povo para todo o sempre.

Ìwọ ti sọ orílẹ̀-èdè di ńlá;

wọ́n yọ̀ níwájú rẹ

gẹ́gẹ́ àwọn ènìyàn ti í yọ ayọ̀ ìkórè,

gẹ́gẹ́ ènìyàn ti í yọ̀

nígbà à ń pín ìkógun.

Kígbe sókè o kọrin fún ayọ̀, ̀yin ènìyàn Sioni,

nítorí títóbi ni ẹni mímọ́ kan ṣoṣo

ti Israẹli láàrín yín."

àwọn ẹni ìràpadà Olúwa yóò padà .

Wọn yóò wọ Sioni pẹ̀orin;

ayọ̀ ayérayé ni yóò wọn orí.

Ìdùnnú àti ayọ̀ ni yóò borí i wọn,

ìkorò àti ìtìjú yóò kúrò lọ́dọ̀ wọn.

Èmi yọ̀ gidigidi nínú Olúwa;

ọkàn mi yọ̀ nínú Ọlọ́run mi.

Nítorí ó ti wọ̀ aṣọ ìgbàlà

ó ṣe lọ́ṣọ̀́ nínú aṣọ òdodo;

gẹ́gẹ́ ọkọ ìyàwó ti ṣe orí rẹ̀ lọ́ṣọ̀́ àlùfáà,

àti ìyàwó ṣe ń ṣe ara rẹ̀ lọ́ṣọ̀́ pẹ̀ohun ̀ṣọ́.

Èmi yọ̀ gidigidi nínú Olúwa;

ọkàn mi yọ̀ nínú Ọlọ́run mi.

Nítorí ó ti wọ̀ aṣọ ìgbàlà

ó ṣe lọ́ṣọ̀́ nínú aṣọ òdodo;

gẹ́gẹ́ ọkọ ìyàwó ti ṣe orí rẹ̀ lọ́ṣọ̀́ àlùfáà,

àti ìyàwó ṣe ń ṣe ara rẹ̀ lọ́ṣọ̀́ pẹ̀ohun ̀ṣọ́.

Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀rẹ,

Ó agbára láti gbà .

Yóò yọ̀ ni orí rẹ fún ayọ̀;

Yóò tún ṣe nínú ìfẹ́ rẹ̀,

Yóò fi orin yọ̀ orí rẹ."

Lọ jẹ oúnjẹ rẹ pẹ̀ayọ̀, o mu ọtí wáìnì rẹ pẹ̀inú dídùn ọkàn, nítorí ìsinsin yìí ni Ọlọ́run síjú àánú wo ohun o ṣe.

ayọ̀ ìgbàlà rẹ tọ̀ ,

o fún mi ̀ìfẹ́, yóò mi dúró.

Dájúdájú, ìwọ ti fi ìbùkún ayérayé fún un:

ìwọ inú rẹ̀ dùn pẹ̀ayọ̀ ojú u rẹ̀.

Nígbà àníyàn ńlá nínú mi,

ìtùnú rẹ̀ ayọ̀ ọkàn mi.

Olúwa ni agbára mi àti asà mi;

nínú rẹ̀ ni mo gbẹ́kẹ̀; àní, ó ràn lọ́wọ́.

Ọkàn mi gbé sókè fún ayọ̀

àní pẹ̀orin mi mo fi ọpẹ́ fún un.

Ìrètí olódodo ni ayọ̀,

ṣùgbọ́n ìrètí ènìyàn búburú jásí òfo.

Inú ènìyàn a máa dùn nígbà ó fèsì yẹ

̀rọ̀ ó lásìkò yẹ dára púpọ̀!

Inú ènìyàn a máa dùn nígbà ó fèsì yẹ

̀rọ̀ ó lásìkò yẹ dára púpọ̀!

Baba olódodo ni yóò yọ̀ gidigidi:

ẹni ó ọmọ ọlọ́gbọ́n,

yóò ayọ̀ nínú rẹ̀.

máa yọ̀ nígbà gbogbo. máa gbàdúrà nígbà gbogbo. máa dúpẹ́ nígbà gbogbo nínú ipòkípò o ; nítorí , èyí ni ìfẹ́ Ọlọ́run fún yin nínú Kristi Jesu nítòótọ́.

Mo fún yín, gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni ayọ̀ yóò ̀run lórí ẹlẹ́ṣẹ̀ kan ó ronúpìwàdà, ju lórí olóòtítọ́ mọ́kàndínlọ́gọ́rùn-ún lọ, nílò ìrònúpìwàdà.

Òwe ìṣúra a fi pamọ́ sínú ilẹ̀ àti ohun ̀ṣọ́ olówó iyebíye

"Ìjọba ̀run dàbí ìṣúra kan a fi pamọ́ sínú oko. Nígbà ọkùnrin kan i ó tún fi í pamọ́. Nítorí ayọ̀ rẹ̀, ó ta gbogbo ohun ìní rẹ̀, ó ra oko náà.

Seja o primeiro
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-