Publicidade

Salmos 149

1 fi ìyìn fún Olúwa.

kọrin tuntun Olúwa.

yìn ín àwùjọ àwọn ènìyàn mímọ́.

2 Jẹ́ Israẹli ó inú dídùn ẹni ó a

jẹ́ àwọn ọmọ Sioni ó

ayọ̀ nínú ọba wọn.

3 Jẹ́ wọn ó fi ijó yin orúkọ rẹ̀

jẹ́ wọn ó fi ohun èlò orin kọrin ìyìn i.

4 Nítorí Olúwa inú dídùn àwọn ènìyàn rẹ̀

ó fi ìgbàlà àwọn onírẹ̀lẹ̀ ládé.

5 Jẹ́ àwọn ènìyàn mímọ́ ó yọ̀ nínú ọlá rẹ̀

wọn ó máa kọrin fún ayọ̀ orí ibùsùn wọn.

6 ìyìn Ọlọ́run ó ẹnu wọn

àti idà olójú méjì ọwọ́ wọn.

7 Láti gba ̀san lára àwọn orílẹ̀-èdè,

àti ìjìyà lára àwọn ènìyàn,

8 láti fi ̀wọ̀n de àwọn ọba wọn

àti láti fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀

irin de àwọn ọlọ́wọn.

9 Láti ṣe ìdájọ́ àkọsílẹ̀ rẹ̀ wọn

èyí ni ògo àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀.

fi ìyìn fún Olúwa.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-