Publicidade

Salmos 126

Orin fún ìgòkè.

1 Nígbà Olúwa ìkólọ Sioni padà,

àwa dàbí ẹni ó ń àlá.

2 Nígbà náà ni ẹnu wa kún fún ̀rín,

àti ahọ́n wa kọ orin;

nígbà náà ni wọ́n nínú àwọn kèfèrí ,

Olúwa ṣe ohun ńlá fún wọn.

3 Olúwa ṣe ohun ńlá fún wa;

nítorí náà àwa ń yọ̀.

4 Olúwa ìkólọ wa padà,

ìṣàn omi gúúsù.

5 Àwọn ń fi omijé fún irúgbìn

yóò fi ayọ̀ ka.

6 Ẹni ń fi ẹkún rìn lọ,

ó gbé irúgbìn lọ́wọ́,

lóòtítọ́, yóò fi ayọ̀ padà ,

yóò ru ìtí rẹ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-