Publicidade

Salmos 47

Fún adarí orin. Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu.

1 pàtẹ́wọ́, gbogbo ̀yin ènìyàn

Ọlọ́run pẹ̀orin ayọ̀ rinlẹ̀.

2 Báwo ni Olúwa ̀gá-ògo ti ̀

ọba ńlá lórí gbogbo ayé.

3 Ṣe ìkápá àwọn orílẹ̀-èdè lábẹ́ wa

àwọn ènìyàn lábẹ́ ẹsẹ̀ wa

4 Ó ilẹ̀ ìní wa fún wa,

ọlá Jakọbu, ẹni ó fẹ́ wa.

5 Ọlọ́run gòkè lọ òun tayọ̀,

Olúwa ti òun ti ariwo ìpè.

6 kọrin ìyìn Ọlọ́run, kọrin ìyìn.

kọrin ìyìn ọba wa, kọrin ìyìn!

7 Nítorí Ọlọ́run ni ọba gbogbo ayé,

kọrin ìyìn pẹ̀Saamu!

8 Ọlọ́run jẹ ọba lórí gbogbo kèfèrí;

Ọlọ́run jókòó lórí ìtẹ́ ìwà mímọ́ rẹ̀.

9 Àwọn aládé ayé ara wọn jọ

gẹ́gẹ́ ènìyàn Ọlọ́run Abrahamu

nítorí asà ayé ti Ọlọ́run ni,

òun ni ó ga jùlọ.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-