Publicidade

Isaías 9

A ọmọ kan fún wa

1 9.1-2: Mt 4.15-16; Lk 1.79. Síbẹ̀síbẹ̀, ìpòrúru kankan mọ́ fún àwọn ó nínú ìbànújẹ́. Nígbà kan ó rẹ ilẹ̀ Sebuluni sílẹ̀ àti ilẹ̀ Naftali pẹ̀, ṣùgbọ́n ọjọ́ iwájú, yóò bu ̀wọ̀ fún Galili ti àwọn aláìkọlà, ̀Òkun, ̀gbẹ̀̀gbẹ́ Jordani.

2 Àwọn ènìyàn ń rìn nínú òkùnkùn

ti ìmọ́lẹ̀ ńlá;

lórí àwọn ń gbé nínú ilẹ̀ òjìji ikú,

ara wọn ni ìmọ́lẹ̀ mọ́ .

3 Ìwọ ti sọ orílẹ̀-èdè di ńlá;

wọ́n yọ̀ níwájú rẹ

gẹ́gẹ́ àwọn ènìyàn ti í yọ ayọ̀ ìkórè,

gẹ́gẹ́ ènìyàn ti í yọ̀

nígbà à ń pín ìkógun.

4 Nítorí gẹ́gẹ́ ọjọ́ a ṣẹ́gun Midiani,

ìwọ ti fọ́ túútúú

àjàgà ti ń pa wọ́n lẹ́,

̀ó dábùú èjìká wọn,

̀gọ aninilára wọn.

5 Gbogbo bàtà jagunjagun a ti lójú ogun

àti gbogbo ̀a nínú ̀jẹ̀,

ni yóò fún ìjóná,

àti ohun èlò iná dídá.

6 Nítorí a ọmọ kan fún wa,

a fi ọmọkùnrin kan fún wa,

ìjọba yóò èjìká rẹ̀.

A ó máa é

Ìyanu Olùdámọ̀ràn, Ọlọ́run Alágbára,

Baba ayérayé, Ọmọ ọba aládé Àlàáfíà.

7 ti gbígbòòrò Ìjọba rẹ̀ àti àlàáfíà rẹ̀ ni yóò ìpẹ̀kun.

Yóò jẹ ọba lórí ìtẹ́ Dafidi

àti lórí ̀kún un rẹ̀ gbogbo,

nípa ìfìdímúlẹ̀ àti ìgbéró rẹ̀,

pẹ̀òtítọ́ àti òdodo

láti ìgbà náà lọ àti títí láéláé.

Ìtara Olúwa àwọn ọmọ-ogun

ni yóò èyí ṣẹ.

Ìbínú Olúwa Israẹli

8 Olúwa ti dojú iṣẹ́ kan kọ Jakọbu;

yóò sórí Israẹli.

9 Gbogbo ènìyàn ni yóò mọ̀ ́n

Efraimu àti gbogbo olùgbé Samaria

ó sọ pẹ̀ìgbéraga

àti gààrù àyà .

10 Àwọn bíríkì ti lulẹ̀

ṣùgbọ́n a ó tún un kọ́ pẹ̀òkúta dídán,

a ti àwọn igi sikamore lulẹ̀

ṣùgbọ́n igi kedari a ó fi dípò wọn.

11 Ṣùgbọ́n Olúwa fún àwọn ̀Resini agbára láti dojúkọ wọ́n

ó ti àwọn ̀wọn sókè.

12 Àwọn ará Aramu láti ìlà-oòrùn àti Filistini láti ìwọ̀-oòrùn.

Wọ́n fi gbogbo ẹnu jẹ Israẹli run.

gbogbo èyí ìbínú rẹ̀ kúrò

ṣùgbọ́n ọwọ́ rẹ̀ jáde síbẹ̀.

13 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn náà ì yípadà

ẹni náà ó wọ́n

bẹ́̀ ni wọ́n Olúwa àwọn ọmọ-ogun.

14 Nítorí náà ni Olúwa yóò ṣe àti orí àti ìrù

kúrò Israẹli,

àti ̀̀pẹ àti koríko odò ọjọ́ kan ṣoṣo,

15 àwọn àgbàgbà, àti àwọn gbajúmọ̀ orí,

àwọn wòlíì ń kọ́ni irọ́ ni ìrù.

16 Àwọn ó ń tọ́ àwọn ènìyàn wọ̀nyí ṣì wọ́n lọ́,

àwọn a tọ́ ni a ń sin ìparun.

17 Nítorí náà, Olúwa yóò dunnú àwọn ̀dọ́mọkùnrin

tàbí ó káàánú àwọn aláìní baba àti opó,

nítorí gbogbo wọn jẹ́ ìkà àti aláìmọ Ọlọ́run,

ibi ni ó ti ẹnu wọn jáde.

Síbẹ̀, fún gbogbo èyí, ìbínú rẹ̀ kúrò

ọwọ́ rẹ̀ gbígbéró.

18 Nítòótọ́ ìwà búburú ń jóni iná,

yóò ̀wọ̀n àti ̀gún run,

yóò rán nínú pàǹtí igbó,

bẹ́̀ yóò fi gòkè lọ ̀wọ́n èéfín ti í gòkè.

19 Nípasẹ̀ ìbínú Olúwa àwọn ọmọ-ogun

ilẹ̀ náà yóò di gbígbẹ

àwọn ènìyàn yóò di ohun ìdáná,

ẹnìkan yóò arákùnrin rẹ̀ .

20 apá ̀tún wọn yóò jẹrun,

síbẹ̀ ebi yóò máa pa wọ́n,

apá òsì, wọn yóò jẹ,

ṣùgbọ́n, tẹ́ wọn lọ́rùn.

Ẹnìkọ̀̀kan yóò máa jẹ ẹran-ara apá rẹ̀.

21 Manase yóò máa jẹ Efraimu, nígbà Efraimu yóò jẹ Manase

wọn yóò parapọ̀ dojúkọ Juda.

Síbẹ̀síbẹ̀, ìbínú un rẹ̀ kúrò

Ọwọ́rẹ̀ gbígbéró.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-