Publicidade

Alimento

Por Bíblia Online

O alimento é provisão de Deus para o corpo e a alma. Jesus disse: Eu sou o pão da vida. A Bíblia ensina a receber com gratidão, partilhar com generosidade e confiar no Provedor.

O pão da vida

Jesus disse: Eu sou o pão da vida. Quem vem a mim nunca terá fome. O alimento espiritual sacia plenamente.

Jesu fún wọn , "Èmi ni oúnjẹ ìyè, ẹnikẹ́ni ó tọ̀ , ebi yóò pa á; ẹni ó gbà gbọ́, òǹgbẹ yóò gbẹ ́ mọ́ láé.

ṣe ṣiṣẹ́ fún oúnjẹ ń ṣègbé, ṣùgbọ́n fún oúnjẹ ó títí di ayé àìnípẹ̀kun, èyí Ọmọ Ènìyàn yóò fi fún yín. Nítorí òun ni, àní Ọlọ́run Baba ti fi èdìdì í."

Ṣùgbọ́n Jesu dáhùn , "A ti kọ ìwé rẹ̀ : Ènìyàn yóò láààyè nípa àkàrà nìkan, ṣe nípa gbogbo ̀rọ̀ ti ó ti ẹnu Ọlọ́run jáde .’ "

Alábùkún fún ni àwọn ebi ń pa

òǹgbẹ ń gbẹ́ nítorí òdodo, nítorí wọn yóò .

Ṣùgbọ́n, kọ́kọ́ ìjọba Ọlọ́run àti òdodo rẹ̀, yóò fi gbogbo àwọn nǹkan wọ̀nyí kún un fún yín pẹ̀.

ṣe àníyàn

"Nítorí náà, mo fún yín, ṣe ṣe àníyàn nípa ̀yín, ohun ó jẹ àti èyí ó mu; tàbí nípa ara yín, ohun ó wọ̀. Ṣé ̀ha ṣe pàtàkì ju oúnjẹ lọ tàbí ara ni ha ṣe pàtàkì ju aṣọ lọ?

ọmọ ọwọ́ tuntun, máa fẹ́ wàrà ti ̀, èyí lẹ́tàn, ̀yin máa tipasẹ̀ rẹ̀ dàgbà ìgbàlà,

Provisão divina

Deus provê alimento em abundância. Ele multiplica pães e peixes, enche os famintos e supre toda necessidade.

Nígbà náà ni ó ìṣù àkàrà márùn-ún, àti ẹja méjì náà, nígbà ó gbé ojú sókè ̀run, ó súre i, ó ú, ó fi fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, wọn gbé e kalẹ̀ níwájú àwọn ènìyàn. Wọ́n jẹ, gbogbo wọn : wọ́n ṣa agbọ̀n méjìlá jọ nínú àjẹkù ó .

nítorí ó tẹ́ ìfẹ́ ọkàn lọ́run

ó fi ìre fún ọkàn ebi ń pa.

gbogbo ìdámẹ́wàá ilé ìṣúra, oúnjẹ à ilé mi, fi èyí dán mi ," Olúwa àwọn ọmọ-ogun , "èmi àwọn fèrèsé ̀run fún yin, èmi ìbùkún àkúnwọ́sílẹ̀ jáde fún yín, bẹ́̀ yóò ààyè láti gbà á.

Ǹjẹ́ ẹni ń fi irúgbìn fún afúnrúgbìn, àti àkàrà fún oúnjẹ, yóò fi irúgbìn fún un yín, yóò sọ ́ di púpọ̀, yóò èso òdodo yín i.

Ẹni ń ṣoore yóò máa gbèrú i;

ẹni ó tu ẹlòmíràn lára yóò ìtura.

̀rọ̀ ìtura dàbí afárá oyin

ó dùn fún ọkàn, ó fi ìlera fún egungun.

Nehemiah , "lọ gbádùn oúnjẹ yàn láàyò ohun dídùn, díẹ̀ ránṣẹ́ àwọn . Ọjọ́ yìí, mímọ́ ni fún Olúwa wa. ṣe banújẹ́, nítorí ayọ̀ Olúwa ni agbára yín."

Gratidão e moderação

Nada trouxemos para o mundo e nada levaremos. Tudo o que fizerdes, fazei para a glória de Deus — inclusive comer e beber.

Nítorí a ohun kan ayé, bẹ́̀ ni a mu ohunkóhun jáde lọ. a ni oúnjẹ àti aṣọ, ìwọ̀nyí yẹ́ ó tẹ́ wa lọ́rùn.

Nítorí náà ̀yin jẹ tàbí mu tàbí ohunkóhun ̀yin , e máa ṣe gbogbo rẹ̀ fún ògo Ọlọ́run.

Wọ́n fi ọkàn kan dúró lójoojúmọ́ nínú tẹmpili. Wọ́n ń bu àkàrà ilé wọn, wọn ń fi inú dídùn àti ọkàn òtítọ́ jẹ oúnjẹ wọn. Wọ́n yín Ọlọ́run, wọn ojúrere lọ́dọ̀ ènìyàn gbogbo, Olúwa ń yàn kún wọn lójoojúmọ́, àwọn à ń gbàlà.

Kíyèsi i, èmi dúró ni ẹnu ìlẹ̀kùn, èmi ń kànkùn, ẹnikẹ́ni gbọ́ ohun mi, ó ṣí ìlẹ̀kùn, èmi yóò wọlé tọ̀ ́ , èmi yóò máa a jẹun, àti òun pẹ̀mi.

ẹni ń jẹ ohun gbogbo ṣe kẹ́gàn ẹni jẹ; ẹni jẹ ohun gbogbo ó ṣe ẹni ń jẹ lẹ́bi nítorí Ọlọ́run ti gbà á.

Nítorí náà ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni ṣe ìdájọ́ yín ti jíjẹ, tàbí ti mímu, tàbí ti ọjọ́ àsè, tàbí oṣù tuntun, àti ọjọ́ ìsinmi. Àwọn í ṣe òjìji ohun ń bọ̀; ṣùgbọ́n ti òtítọ́, nínú Kristi ni àti mu wọn ṣẹ.

Ó rẹ̀ yín sílẹ̀ nípa fífi ebi pa yín, Ó fi manna bọ́ yín, èyí mọ̀, àwọn baba yín mọ̀, ó ba à kọ́ yín , ènìyàn ti ipa oúnjẹ nìkan láààyè, ṣe ohun gbogbo ó jáde láti ẹnu Olúwa .

Nínú gbogbo ̀alààyè ń gbé inú omi, jẹ èyíkéyìí ó lẹbẹ àti ìpẹ́. Ṣùgbọ́n èyíkéyìí lẹbẹ àti ìpẹ́, ṣe jẹ ́, nítorí àìmọ́ ni wọ́n jẹ́ fún yín.

Nígbà náà ni Ọlọ́run , "Mo fi gbogbo ohun ̀gbìn ń so èso fún un yín oúnjẹ àti àwọn igi eléso pẹ̀. Gbogbo rẹ̀ yóò jẹ́ oúnjẹ fún un yín.

Gbogbo ohun láààyè ó ń rìn, ni yóò jẹ́ oúnjẹ fún un yín, mo ṣe fi ewéko fún un yín náà ni mo fi ohun gbogbo fún un yín.

"Ṣùgbọ́n ̀yin gbọdọ̀ jẹ ẹran tòun-tẹ̀jẹ̀ rẹ̀.

Èmi í jẹ oúnjẹ ó dára, èmi fi ẹran tàbí wáìnì kan ẹnu mi, bẹ́̀ ni èmi fi òróró para títí ̀sẹ̀ mẹ́ta fi kọjá.

Seja o primeiro
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-