Publicidade

Deuteronômio 14

Oúnjẹ ó mọ́ àti èyí mọ́

1 14.1: Le 19.28. Ọmọ Olúwa Ọlọ́run yín ni ̀yin jẹ́: nítorí náà, ṣe ya ara yín abẹ. ṣe irun iwájú orí yín nítorí òkú. 2 14.2: Ek 19.5,6; De 26.19; Tt 2.14; 1Pt 2.9; If 1.6; 5.10.Nítorí ènìyàn mímọ́ jẹ́ fún Olúwa Ọlọ́run yín, nínú gbogbo ènìyàn ó lórí ilẹ̀ ayé, Ọlọ́run ti yàn yín láti jẹ́ ìṣúra iyebíye rẹ̀.

3 14.3-20: Le 11.2-23. ṣe jẹ ohun ìríra kankan. 4 Àwọn wọ̀nyí ni ẹranko máa jẹ: màlúù, àgùntàn àti ewúrẹ́, 5 àgbọ̀nrín, èsúró, etu, àgóró, ẹfọ̀n, ìgalà àti àgùntàn igbó. 6 jẹ gbogbo ẹranko pátákò ẹsẹ̀ rẹ̀ í ṣe méjì ó tún jẹ àpọ̀jẹ. 7 Síbẹ̀síbẹ̀ nínú gbogbo ẹran ń jẹ àpọ̀jẹ ó tún ya pátákò ẹsẹ̀ gbọdọ̀ jẹ ni: ìbákasẹ, ehoro, àti ẹranko ó dàbí ehoro ń gbé inú àpáta. ó tilẹ̀ jẹ́ wọ́n jẹ àpọ̀jẹ, ṣùgbọ́n wọn la pátákò ẹsẹ̀, a wọ́n àìmọ́ fún yín. 8 Ẹlẹ́dẹ̀ jẹ́ àìmọ́; ó tilẹ̀ jẹ́ ó ya pátákò ẹsẹ̀, í jẹ àpọ̀jẹ, gbọdọ̀ jẹ ẹran rẹ̀, gbọdọ̀ fọwọ́ kan òkú rẹ̀.

9 Nínú gbogbo ̀alààyè ń gbé inú omi, jẹ èyíkéyìí ó lẹbẹ àti ìpẹ́. 10 Ṣùgbọ́n èyíkéyìí lẹbẹ àti ìpẹ́, ṣe jẹ ́, nítorí àìmọ́ ni wọ́n jẹ́ fún yín.

11 jẹ ẹyẹ ó mọ́. 12 Ṣùgbọ́n ìwọ̀nyí gbọdọ̀ jẹ: idì, igún, àkàlà, 13 onírúurú àṣá àti àṣá alátagbà, 14 onírúurú ẹyẹ ìwò, 15 ògòǹgò, òwìwí, pẹ́pẹ́yẹdò àti onírúurú àwòdì, 16 onírúurú òwìwí, 17 òwìwí ̀dàn, àkàlà, ìgò, 18 àkọ̀, òòdẹ̀, onírúurú ẹyẹ odò mìíràn, atọ́ka àti àdán.

19 Àti gbogbo kòkòrò ń wọ́n ń kọ́wọ̀́ rìn jẹ́ aláìmọ́ fun un yín, ṣe jẹ wọ́n. 20 Ṣùgbọ́n jẹ èyíkéyìí ̀abìyẹ́ ó mọ́.

21 14.21: Le 11.39,40; 17.15; El 23.19; 34.26. ṣe jẹ ohun ó ti sílẹ̀. fún àwọn àjèjì ń gbé èyíkéyìí nínú ìlú yín. Òun jẹ ́ tàbí á fún àwọn àjèjì. Ṣùgbọ́n ènìyàn mímọ́ fún Olúwa Ọlọ́run yín ni ̀yin jẹ́.

Ìwọ gbọdọ̀ ṣe ewúrẹ́ nínú wàrà ìyá rẹ̀.

Ìdámẹ́wàá

22 14.22-29: Le 27.30-33; Nu 18.21-32. i dájú ̀ ń fi ìdákan nínú mẹ́wàá nínú ìre oko yín lọ́dọọdún pamọ́ apá kan. 23 jẹ ìdámẹ́wàá oúnjẹ yín, wáìnì tuntun, òróró, àti àkọ́àwọn màlúù yín àti ewúrẹ́ yín, níwájú Olúwa Ọlọ́run yín, ibi yóò yàn ibùgbé orúkọ rẹ̀. kọ́ a ṣé ń bu ọlá fún Olúwa Ọlọ́run yín nígbà gbogbo. 24 ibẹ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ ti bùkún fún , o le ru àwọn ìdámẹ́wàá rẹ (nítorí ibi Olúwa yóò yàn láti fi orúkọ rẹ̀ jìnnà ). 25 pààrọ̀ àwọn ìdámẹ́wàá yín owó, owó náà lọ ibi Olúwa yóò yàn. 26 Fi owó náà ra ohunkóhun o fẹ́, màlúù, àgùntàn, wáìnì, tàbí ọtí líle, tàbí ohunkóhun o fẹ́. ìwọ àti ìdílé rẹ jẹ ́ níwájú Olúwa níbẹ̀ máa yọ̀. 27 ṣe gbàgbé àwọn Lefi ó ń gbé ìlú yín, nítorí wọn ìpín kan tàbí ogún kan í ṣe tiwọn.

28 òpin ọdún mẹ́ta mẹ́ta, ̀yin yóò gbogbo ìdámẹ́wàá ìre oko àwọn ọdún náà, wọn jọ ìlú yín. 29 àwọn Lefi (ìpín tàbí ogún tiwọn) àti àwọn àjèjì, àwọn aláìní baba, àti àwọn opó ń gbé ìlú yín , wọn jẹ wọn , Olúwa Ọlọ́run rẹ le è bùkún fún , nínú gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-