Publicidade

Criação

Por Bíblia Online

A criação revela a glória de Deus. Céus, terra, mares e tudo o que existe testemunham o poder criador. No princípio Deus criou — e tudo era muito bom.

No princípio

No princípio criou Deus os céus e a terra. O Espírito de Deus pairava sobre as águas. E Deus disse: haja luz.

Ìbẹ̀rẹ̀ dídá ayé

ìbẹ̀rẹ̀ ohun gbogbo Ọlọ́run àwọn ̀run àti ayé. Ayé rúdurùdu, ó ṣófo, òkùnkùn lójú ibú omi, ̀Ọlọ́run ń rábàbà lójú omi.

Lẹ́yìn náà ni Ọlọ́run , "jẹ́ a ènìyàn àwòrán ara wa, gẹ́gẹ́ àwa ti , wọn ó jẹ ọba lórí ẹja òkun, ẹyẹ ojú ̀run, ẹran ̀sìn, gbogbo ilẹ̀ àti lórí ohun gbogbo ń rìn lórí ilẹ̀."

Nítorí náà, Ọlọ́run ènìyàn àwòrán ara rẹ̀,

àwòrán Ọlọ́run ni ó a,

akọ àti abo ni ó wọn.

Ọlọ́run súre fún ọjọ́ keje, ó á mímọ́, nítorí ọjọ́ náà ni ó sinmi kúrò nínú iṣẹ́ dídá ayé ó ti ń ṣe.

Olúwa Ọlọ́run , "dára ọkùnrin òun nìkan. Èmi yóò ṣe olùrànlọ́wọ́ ó i rẹ̀ fún un."

O poder criador

Pela palavra do Senhor foram feitos os céus. Tudo foi criado por Ele e para Ele — o visível e o invisível.

Nípasẹ̀ ̀rọ̀ Olúwa ni a ṣe àwọn ̀run,

àti gbogbo àwọn ẹgbẹ́ ogun wọn nípa ìmísí ẹnu rẹ̀.

a àwọn òkè ńlá

àti ìwọ ilẹ̀ àti ayé,

láti ayérayé ayérayé ìwọ ni Ọlọ́run.

, jẹ́ a foríbalẹ̀ a sìn ín,

jẹ́ a kúnlẹ̀ níwájú

Olúwa ẹni ó wa,

Orin fún ìgòkè.

Èmi yóò gbé ojú mi sórí òkè wọ̀n-ọn-nì

níbo ni ìrànlọ́wọ́ mi yóò ti ?

Ìrànlọ́wọ́ mi ọwọ́ Olúwa ,

ẹni ó ̀run òun ayé.

Ìrànlọ́wọ́ wa ń bẹ orúkọ Olúwa,

ó ̀run òun ayé.

Èyí ni ọjọ́ Olúwa :

jẹ́ ayọ̀ inú wa máa dùn nínú rẹ̀.

Nítorí ìwọ ni ó ọkàn mi;

ìwọ ni ó mọ́lẹ̀ nínú ìyá mi.

Èmi yóò yìn , nítorí tẹ̀tẹ̀àti tìyanu tìyanu a mi;

ìyanu iṣẹ́ rẹ;

èyí ni ọkàn mi mọ̀ dájúdájú.

Criador e Sustentador

O Deus eterno não se cansa nem se fatiga. Dele, por Ele e para Ele são todas as coisas — a Ele seja a glória.

Ìwọ ì mọ̀?

Ìwọ ì gbọ́?

Olúwa òun ni Ọlọ́run ayérayé,

Ẹlẹ́dàá gbogbo ìpẹ̀kun ilẹ̀ ayé.

Agara yóò da bẹ́̀ ni ṣàárẹ̀,

àti òye rẹ̀ ni ẹnikẹ́ni le ṣe òdínwọ̀n rẹ̀.

"Ègbé ni fún ènìyàn ó ń Ẹlẹ́dàá rẹ̀ ,

ẹni òun jẹ́ àpáàdì kan láàrín àwọn àpáàdì ó lórí ilẹ̀.

Ǹjẹ́ amọ̀ sọ fún amọ̀kòkò, :

ni ohun ò ń ṣe?

Ǹjẹ́ iṣẹ́ rẹ sọ ,

Òun ọwọ́?’

"Háà! Olúwa Olódùmarè, ìwọ o ̀run àti ayé pẹ̀títóbi agbára rẹ àti gbogbo ̀rọ̀ apá rẹ. ohun ó ṣòro fún láti ṣe.

Òun ni ẹni ó kọ́ ìtẹ́ rẹ̀ nínú àwọn ̀run

ti ó fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ ilé ayé,

Ẹni ti ó pe àwọn omi Òkun

ti ó wọn jáde si orí ilé ayé

Olúwa ni orúkọ rẹ̀.

Nítorí láti ̀dọ̀ rẹ̀, àti nípa rẹ̀, àti fún un ni ohun gbogbo;

ẹni ògo fún láéláé! Àmín.

Nítorí láti ìgbà dídá ayé, gbogbo ohun àìlèfojúrí rẹ̀, agbára ayérayé àti ìwà-bí-Ọlọ́run rẹ̀ ni a gbangba a ń fi òye ohun a mọ̀ ́n ènìyàn ba à àwáwí.

Nítorí ̀ń dúró ìfojúsọ́de ìfihàn àwọn ọmọ Ọlọ́run.

Nova criação

Se alguém está em Cristo, nova criatura é. O Criador faz novas todas as coisas — na natureza e na redenção.

Nítorí náà ẹnìkan nínú Kristi, ó di ̀tuntun: ohun àtijọ́ ti kọjá lọ; kíyèsi i, ohun tuntun ti .

Nítorí àwa ni iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀ a ti nínú Kristi Jesu fún àwọn iṣẹ́ rere, èyí Ọlọ́run ti pèsè tẹ́lẹ̀, fún wa láti ṣe.

Ó pinnu láti fi ̀rọ̀ òtítọ́ wa àwa ó le jẹ́ àkọ́so nínú ohun gbogbo ó .

Láti ọwọ́ ènìyàn kan ni a à ti kọ́ olúkúlùkù ilé; ṣùgbọ́n ẹni ó kọ́ ohun gbogbo ni Ọlọ́run.

Nítorí nínú rẹ̀ ni àwa láààyè, a ń rìn kiri, a ̀wa, àwọn kan nínú àwọn akéwì ̀yin tìkára yín , Àwa pẹ̀jẹ́ ọmọ rẹ̀.’

Gbogbo ̀o ń bẹ ni ̀run, àti lórí ilẹ̀ ayé, àti nísàlẹ̀ ilẹ̀ àti irú àwọn ń bẹ nínú Òkun, àti gbogbo àwọn ń bẹ nínú wọn, ni mo gbọ́ ń ,

"a fi ìbùkún àti ọlá, àti ògo, àti agbára,

fún Ẹni ó jókòó lórí ìtẹ́ àti fún ̀dọ́-àgùntàn

náà láé àti láéláé."

Seja o primeiro
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_15-35-42-