Publicidade

Salmos 121

Orin fún ìgòkè.

1 Èmi yóò gbé ojú mi sórí òkè wọ̀n-ọn-nì

níbo ni ìrànlọ́wọ́ mi yóò ti ?

2 Ìrànlọ́wọ́ mi ọwọ́ Olúwa ,

ẹni ó ̀run òun ayé.

3 Òun yóò jẹ́ ẹsẹ̀ rẹ ó yẹ̀;

ẹni ó pa ́ mọ́ í tòògbé.

4 Kíyèsi, ẹni ń pa Israẹli mọ́,

í tòògbé bẹ́̀ ni í sùn.

5 Olúwa ni olùpamọ́ rẹ;

Olúwa òjìji rẹ ọwọ́ ̀tún rẹ.

6 Oòrùn yóò pa ́ ìgbà ̀sán

tàbí òṣùpá ìgbà òru.

7 Olúwa yóò pa ́ mọ́ kúrò nínú ibi gbogbo

yóò pa ọkàn rẹ mọ́

8 Olúwa yóò pa àlọ àti ààbọ̀ rẹ mọ́

láti ìgbà yìí lọ àti títí láéláé.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-