Publicidade

Salmos 139

Fún adarí orin. Ti Dafidi. Saamu.

1 Olúwa, ìwọ wádìí mi,

ìwọ ti mọ̀ .

2 Ìwọ mọ̀ ìjókòó mi àti ìdìde mi,

ìwọ mọ̀ èrò mi ̀jíjìn réré.

3 Ìwọ ipa ̀mi àti ìdùbúlẹ̀ mi,

gbogbo ̀mi di mọ̀ fún .

4 Nítorí ̀rọ̀ kan ahọ́n mi,

kíyèsi i, Olúwa, ìwọ mọ̀ ́n pátápátá.

5 Ìwọ mi mọ́ lẹ́yìn àti níwájú,

ìwọ fi ọwọ́ rẹ mi.

6 Irú ìmọ̀ yìí jẹ ohun ìyanu fún mi ;

ó ga, èmi le mọ̀ ́n.

7 Níbo èmi yóò gbé lọ kúrò ni ọwọ́ ̀rẹ?

Tàbí níbo ni èmi yóò sáré kúrò níwájú rẹ?

8 èmi gòkè lọ ̀run, ìwọ níbẹ̀;

èmí ba tẹ́ ẹní mi ipò òkú,

kíyèsi i, ìwọ níbẹ̀ pẹ̀.

9 Èmi ìbá ìyẹ́ apá òwúrọ̀,

èmi lọ jókòó ìhà òpin Òkun,

10 àní, níbẹ̀ náà ni ọwọ́ rẹ̀ yóò

ọwọ́ ̀tún rẹ yóò mímú.

11 mo , "Ǹjẹ́ òkùnkùn ó mọ́lẹ̀;

ìmọ́lẹ̀ ó di òru mi ."

12 Nítòótọ́ òkùnkùn í ṣú lọ́dọ̀ rẹ;

ṣùgbọ́n òru tan ìmọ́lẹ̀ ̀sán;

àti òkùnkùn àti ̀sán, méjèèjì bákan náà fún .

13 Nítorí ìwọ ni ó ọkàn mi;

ìwọ ni ó mọ́lẹ̀ nínú ìyá mi.

14 Èmi yóò yìn , nítorí tẹ̀tẹ̀àti tìyanu tìyanu a mi;

ìyanu iṣẹ́ rẹ;

èyí ni ọkàn mi mọ̀ dájúdájú.

15 ̀ara mi pamọ́ kúrò lọ́dọ̀ rẹ,

nígbà a mi ìkọ̀kọ̀.

a ń ṣiṣẹ́ àràbarà ìhà ìsàlẹ̀ ilẹ̀ ayé,

16 ojú rẹ ti ohun ara mi

nígbà a ì ṣe ,

àti nínú ìwé rẹ ni a ti kọ ̀kọ̀̀kan wọn ,

ọjọ́ a wọn,

nígbà wọn tilẹ̀ ì .

17 Ọlọ́run, èrò inú rẹ ṣe iyebíye fún mi,

iye wọn ti pọ̀ !

18 Èmi ìbá wọ́n,

wọ́n ju iyanrìn lọ iye:

nígbà mo ,

èmi yóò lọ́dọ̀ rẹ síbẹ̀.

19 Ọlọ́run ìbá jẹ́ pa àwọn ènìyàn búburú nítòótọ́;

nítorí náà kúrò lọ́dọ̀ mi ̀yin ọkùnrin ẹlẹ́jẹ̀.

20 Ẹni ń fi inú búburú sọ̀rọ̀ ,

àwọn ̀rẹ ń pe orúkọ rẹ asán!

21 Olúwa, ǹjẹ́ èmi kórìíra àwọn kórìíra rẹ?

Ǹjẹ́ inú mi a bàjẹ́ àwọn ó dìde ?

22 Èmi kórìíra wọn àkótán;

èmi wọ́n ̀mi.

23 Ọlọ́run, wádìí mi, o mọ ọkàn ;

dán mi , o mọ ìrò inú mi.

24 ó ó ipa ̀búburú

kan nínú mi ó

fi ẹsẹ̀ mi ̀àìnípẹ̀kun.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-