Publicidade

Amós 9

A o pa Israẹli run

1 Mo Olúwa, ó dúró ̀pẹpẹ, ó :

"Lu orí àwọn àtẹ́rígbà ìlẹ̀kùn

àwọn òpó ó

fọ́ wọn orí àwọn gbogbo ènìyàn

àwọn ó ṣẹ́ni èmi yóò fi idà pa,

ẹni ó sálọ nínú wọn yóò gbé,

ẹni ti ó àsálà nínú wọn yóò gbàlà.

2 wọ́n tilẹ̀ wa ilẹ̀ lọ ipò òkú,

láti ibẹ̀ ni ọwọ́ mi yóò ti tẹ̀ wọ́n.

wọ́n tilẹ̀ gun òkè ̀run lọ,

láti ibẹ̀ ni èmi yóò ti wọn sọ̀kalẹ̀.

3 wọ́n tilẹ̀ fi ara wọn pamọ́ ni orí òkè Karmeli,

èmi yóò wọn , Èmi yóò si wọn kúrò níbẹ̀.

wọ́n tilẹ̀ fi ara pamọ́ fún mi ìsàlẹ̀ Òkun,

láti ibẹ̀ ni Èmi yóò ti pàṣẹ fún ejò ó wọ́n ṣán.

4 wọ́n tilẹ̀ lọ ìgbèkùn iwájú àwọn ̀wọn

láti ibẹ̀ ni èmi yóò ti pàṣẹ fún idà ó ṣá wọn pa.

"Èmi yóò tẹ ojú mi mọ́ wọn fún ìbí,

í í ṣe fún rere."

5 Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

ẹni ti ó fi ọwọ́ kan ilẹ̀ náà ó yọ́, àwọn olùgbé inú rẹ̀ yóò ṣọ̀fọ̀;

gbogbo orílẹ̀-èdè yóò si ru sókè ríru odò Naili

tiwọn yóò tẹ̀odò Ejibiti.

6 Òun ni ẹni ó kọ́ ìtẹ́ rẹ̀ nínú àwọn ̀run

ti ó fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ ilé ayé,

Ẹni ti ó pe àwọn omi Òkun

ti ó wọn jáde si orí ilé ayé

Olúwa ni orúkọ rẹ̀.

7 "Àbá ̀yin ọmọ Israẹli

ha dàbí àwọn ọmọ Kuṣi mi?"

ni Olúwa .

"Èmi ha ti Israẹli gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti jáde

àti àwọn Filistini láti ilẹ̀ Kafitori

àti àwọn ará Aramu láti Kiri?

8 "Dájúdájú, ojú Olúwa Olódùmarè

ń bẹ̀ lára ilẹ̀ ọba kún fún ̀ṣẹ̀.

Èmi yóò pa á run kúrò lórí ilẹ̀.

Síbẹ̀, Èmi nípa ilé Jakọbu run pátápátá,"

ni Olúwa .

9 "Nítorí Èmi yóò pàṣẹ,

Èmi yóò mi ilé Israẹli

àárín àwọn orílẹ̀-èdè

a ti ń jọ nǹkan nínú ajọ̀

hóró kín ń kín yóò bọ́ sórí ilẹ̀.

10 Gbogbo àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ láàrín àwọn ènìyàn mi

ni yóò ti ipa idà

gbogbo àwọn ti ń ,

Aburú yóò wa , bẹ́̀ ni yóò wa mọ́.’

Ìmúpadàbọ̀ Israẹli

11 9.11-12: Ap 15.16-17. "ọjọ́ náà

Èmi yóò gbé àgọ́ Dafidi ó ,

Èmi yóò odi rẹ̀ ó ya,

Èmi yóò gbé ahoro rẹ̀ sókè,

Èmi yóò kọ ti ọjọ́ ìgbàanì,

12 wọn le jogún ìyókù Edomu

àti gbogbo àwọn kèfèrí, ti a ń nípa orúkọ mi,"

ni Olúwa, ẹni yóò ṣe nǹkan wọ̀nyí .

13 9.13: Jl 3.18. "Ọjọ́ náà ń bọ," ni Olúwa ,

"ẹni ń tulẹ̀ yóò ẹni ń kórè .

ẹni ń fún èso àjàrà yóò ẹni ń gbìn .

Àwọn òkè ńlá yóò kán ọtí wáìnì sílẹ̀,

yóò sàn láti ara àwọn òkè kéékèèké.

14 Èmi yóò si tún ìgbèkùn Israẹli ènìyàn mi padà bọ̀.

"Wọn yóò kọ́ ahoro ìlú, wọn yóò máa gbé inú wọn.

Wọn yóò gbin ọgbà àjàrà, wọn yóò mu ọtí wáìnì wọn

wọn yóò ṣe ọgbà pẹ̀, wọn yóò jẹ èso inú wọn.

15 Èmi yóò gbin Israẹli orí ilẹ̀ rẹ̀.

A yóò wọn tu mọ́ láéláé

kúrò ni orí ilẹ̀ ti mo fi fún wọn,"

ni Olúwa Ọlọ́run rẹ .

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_15-35-42-