Publicidade

Amós 8

Agbọ̀n èso pípọ́n

1 Èyí ni ohun Olúwa Olódùmarè fihàn mi: agbọ̀n èso pípọ́n. 2 Ó béèrè , "Amosi ni ìwọ ."

Mo dáhùn , "Agbọ̀n èso pípọ́n."

Nígbà náà ni Olúwa fún mi , "Àsìkò náà pọ́n fún àwọn ènìyàn mi Israẹli; Èmi yóò wọn mọ́."

3 Olúwa Olódùmarè , "ọjọ́ náà, àwọn orin tẹmpili yóò padà ohùn réré ẹkún. ̀pọ̀, àní ̀pọ̀ ara òkú ni yóò ni ibi gbogbo! Àní ni ìdákẹ́ jẹ́́!"

4 gbọ́ èyí, ̀yin ń tẹ aláìní lórí ba,

ń sọ tálákà di ilẹ̀.

5 ń ,

"Nígbà wo ni oṣù tuntun yóò parí

àwa à ta ọkà

ọjọ́ ìsinmi ó dópin

àwa à le ta jéró?"

a dín ìwọ̀n wa

a gbéraga lórí iye a ó á

a fi òsùwọ̀n èké yàn wọ́n jẹ,

6 àwa fi fàdákà ra àwọn tálákà,

a fi bàtà ẹsẹ̀ méjèèjì ra aláìní,

a ta jéró a mọ́ ilẹ̀.

7 Olúwa ti fi ìgbéraga Jakọbu búra , "Èmi yóò gbàgbé ̀kan nínú ohun wọ́n ṣe.

8 "Ǹjẹ́ ilẹ̀ náà yóò ha wárìrì fún èyí?

Àwọn ń gbé inú rẹ̀ yóò ha ṣọ̀fọ̀?

Gbogbo ilẹ̀ yóò ru sókè omi Naili,

yóò ru ú sókè pátápátá ìkún omi

a ó í jáde, a ó tẹ̀ ́ gẹ́gẹ́ odò Ejibiti.

9 "Yóò ṣe ọjọ́ náà," ni Olúwa Olódùmarè ,

"Èmi yóò oòrùn wọ̀ ̀sán,

Èmi yóò ayé ṣókùnkùn ̀sán gangan.

10 Èmí yóò àsè ̀sìn yín padà ̀fọ̀,

gbogbo orin yín ni èmi yóò sọ di ẹkún.

Èmi yóò gbogbo yín wọ aṣọ ̀fọ̀,

a orí yín.

Èmi yóò ìgbà náà ìṣọ̀fọ̀ fún ọmọkùnrin

kan ṣoṣo a àti òpin rẹ̀ ọjọ́ kíkorò.

11 "Ọjọ́ ń bọ̀," ni Olúwa Olódùmarè ,

"nígbà èmi yóò rán ìyàn ilẹ̀ náà,

í ṣe ìyàn oúnjẹ tàbí òǹgbẹ fún omi.

Ṣùgbọ́n ìyàn gbígbọ́ ̀rọ̀ Olúwa.

12 Àwọn ènìyàn yóò rìn kiri láti Òkun Òkun

wọn yóò máa rìn láti gúúsù àríwá,

wọn yóò máa ̀rọ̀ Olúwa

ṣùgbọ́n wọn yóò i.

13 "ọjọ́ náà

"àwọn arẹwà wúńdíá àti àwọn alágbára ̀dọ́mọkùnrin

yóò dákú fún òǹgbẹ omi.

14 Àwọn ó fi ̀ṣẹ̀ Samaria búra,

wọ́n , ó ti dájú ọlọ́run rẹ ń bẹ láààyè, ìwọ Dani,

ó ti dájú ọlọ́run rẹ ń bẹ láààyè, ìwọ Beerṣeba,

wọ́n yóò ṣubú,

wọn yóò si tún dìde mọ."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-