Publicidade

Atos 10

Àwọn ìpè Korneliu fún Peteru

1 Ọkùnrin kan ni Kesarea ti a ń Korneliu, balógun ̀rún ti ẹgbẹ́ ọmọ-ogun a ń ni Itali. 2 Olùfọkànsìn, àti ẹni ti ó bẹ̀Ọlọ́run tilétilé rẹ̀ gbogbo, ẹni ó ń tọrẹ àánú púpọ̀ fún àwọn ènìyàn, ó ń gbàdúrà sọ́dọ̀ Ọlọ́run nígbà gbogbo. 3 Níwọ́n wákàtí kẹsànán ọjọ́, ó nínú ìran kedere angẹli Ọlọ́run kan wọlé tọ̀ ́ , ó fún un , "Korneliu!"

4 Nígbà ó tẹjúmọ́ ọn, ti ̀á, ó , "Kín ni, Olúwa?"

Ó fún un , "Àdúrà rẹ àti ọrẹ-àánú, tìrẹ gòkè lọ síwájú Ọlọ́run fún ìrántí. 5 rán ènìyàn nísinsin yìí lọ Joppa, wọn pe Simoni , ẹni ti àpèlé rẹ̀ ń jẹ́ Peteru. 6 Ó wọ̀ ilé Simoni aláwọ, ilé rẹ̀ létí Òkun; òun ni yóò sọ fún ìwọ ó ti ṣe."

7 Nígbà angẹli náà ó Korneliu sọ̀rọ̀ fi i sílẹ̀ lọ ó pe méjì nínú àwọn ìránṣẹ́ ilé rẹ̀, àti ọmọ-ogun olùfọkànsìn kan, nínú àwọn ti ó máa ń dúró í nígbà gbogbo. 8 Nígbà ó ṣàlàyé ohun gbogbo fún wọn, ó rán wọn lọ Joppa.

Ìran Peteru

9 Ni ọjọ́ kejì wọ́n ti ń lọ lọ́àjò wọn, wọ́n súnmọ́ ilé náà, Peteru gun òkè ilé lọ láti gbàdúrà ni ìwọ̀n wákàtí kẹfà ọjọ́, 10 ebi pa á gidigidi, ó ń fẹ́ láti jẹun, ó bọ́ ojúran. 11 Ó ̀run ṣí, ohun èlò kan si sọ̀kalẹ̀ gọgọwú ńlá, a ti igun mẹ́rẹ̀̀rin, sọ̀kalẹ̀ ilẹ̀. 12 Nínú rẹ̀ ni onírúurú ẹranko ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́rin , àti ohun ń rákò ni ayé àti ẹyẹ ojú ̀run. 13 Ohùn kan si fọ̀ i pe, "Dìde, Peteru; máa pa o máa jẹ."

14 Ṣùgbọ́n Peteru dáhùn , "Rara, Olúwa; nítorí èmi jẹ ohun èèwọ̀ àti aláìmọ́ kan ."

15 Ohùn kan tún fọ̀ i lẹ́̀méjì , "Ohun Ọlọ́run ti wẹ̀mọ́, ìwọ ṣe é èèwọ̀ mọ́."

16 Èyí ṣe lẹ́̀mẹ́ta; lójúkan náà a gbé ohun èlò náà padà lọ sókè ̀run.

Korneliu ránṣẹ́ Peteru

17 Peteru ti ń dààmú nínú ara rẹ̀ òun ti mọ̀ ìran òun ri yìí , si ó, àwọn ọkùnrin a rán láti ̀dọ̀ Korneliu . Wọ́n ń béèrè ilé Simoni, wọ́n dúró ẹnu-ọ̀. 18 Wọn nahùn béèrè Simoni a ń Peteru, wọ̀ níbẹ̀.

19 Peteru ti ń ronú ìran náà, ̀fún un , "ó, àwọn ọkùnrin mẹ́ta ń . 20 Ǹjẹ́ dìde, sọ̀kalẹ̀ ó wọn lọ, ṣe ara láti wọn lọ, nítorí èmi ni ó rán wọn."

21 Nígbà náà ni Peteru sọ̀kalẹ̀ tọ àwọn ọkùnrin náà a rán, ó , "ó, èmi ni ẹni ̀yin ń , kín ni ìdí rẹ̀ ti fi ?"

22 Wọ́n , "Korneliu balógun ̀rún, ọkùnrin olóòtítọ́, àti ẹni ti ó bẹ̀Ọlọ́run, ó orúkọ rere lọ́dọ̀ gbogbo orílẹ̀-èdè àwọn Júù, òun ni a ti ̀dọ̀ Ọlọ́run kọ́ nípasẹ̀ angẹli mímọ́, láti ránṣẹ́ ́ ilé rẹ̀ àti láti gbọ́ ̀rọ̀ lẹ́nu rẹ." 23 Nígbà náà ni Peteru wọ́n wọlé, ó gbà wọ́n lálejò.

Peteru ilé Korneliu

ọjọ́ kejì, ó dìde, ó wọn lọ, díẹ̀ nínú àwọn ti o ti gbàgbọ́ Joppa a lọ pẹ̀. 24 Lọ́jọ́ kejì wọ́n wọ Kesarea, Korneliu ti ń retí wọn, ó ti pe àwọn ìbátan àti àwọn ̀rẹ́ rẹ̀ tímọ́tímọ́ jọ. 25 Ó ṣe Peteru ti ń wọlé, Korneliu pàdé rẹ̀, ó wólẹ̀ lẹ́sẹ̀ rẹ̀, ó foríbalẹ̀ fún un. 26 Ṣùgbọ́n Peteru gbé e dìde, ó ni, "Dìde ènìyàn ni èmi tìkára mi pẹ̀."

27 ó ti ń a sọ̀rọ̀, ó wọlé ó àwọn ènìyàn púpọ̀ wọ́n péjọ. 28 Ó fún wọn , "̀yin mọ̀ ó ti jẹ́ èèwọ̀ fún ẹni ó jẹ́ Júù, láti ẹni ó jẹ́ ará ilẹ̀ mìíràn kẹ́gbẹ́, tàbí láti tọ̀ ́ ; ṣùgbọ́n Ọlọ́run ti fihàn mi , ki èmi ṣe ẹnikẹ́ni ni èèwọ̀ tàbí aláìmọ́. 29 Nítorí náà ni mo ṣe àìjiyàn, a ti ránṣẹ́ mi, ǹjẹ́ mo béèrè, nítorí kín ̀yin ṣe ránṣẹ́ mi?"

30 Korneliu dáhùn , "ìjẹrin, mo ń ṣe àdúrà wákàtí kẹsànán ọjọ́ ni ilé mi títí di idayìí, ó, ọkùnrin kan aláṣọ, àlà dúró níwájú mi. 31 Ó , Korneliu, a gbọ́ àdúrà rẹ, ọrẹ-àánú rẹ̀ ni ìrántí níwájú Ọlọ́run. 32 Ǹjẹ́ ránṣẹ́ lọ Joppa, ó pe Simoni , ẹni ti àpèlé rẹ̀ ń jẹ́ Peteru; ó wọ̀ ilé Simoni aláwọ létí òkun.33 Nítorí náà ni mo ṣe ránṣẹ́ lójúkan náà, ìwọ ṣeun ó fi . Gbogbo wa níwájú Ọlọ́run nísinsin yìí, láti gbọ́ ohun gbogbo, ti a pàṣẹ fún láti ̀dọ̀ Ọlọ́run ."

34 Peteru ya ẹnu rẹ, ó , "Nítòótọ́ mo wòye , Ọlọ́run í ṣe ojúsàájú ènìyàn. 35 Ṣùgbọ́n ni gbogbo orílẹ̀-èdè, ẹni ó bẹ̀rẹ̀, ti ó ń ṣiṣẹ́ òdodo, ẹni ìtẹ́wọ́gbà ni lọ́dọ̀ rẹ̀. 36 Ẹyin mọ ọrọ̀ Ọlọ́run rán àwọn ọmọ Israẹli láti kéde ìròyìn ayọ̀ àlàáfíà nípasẹ̀ Jesu Kristi, ẹni ti ṣe Olúwa ohun gbogbo. 37 ̀yin náà mọ ̀rọ̀ náà a kéde rẹ̀ yíká gbogbo Judea, a bẹ̀rẹ̀ rẹ̀ láti Galili, lẹ́yìn bamitiisi ti Johanu wàásù rẹ̀. 38 Àní Jesu ti Nasareti, gẹ́gẹ́ Ọlọ́run ti da ̀Mímọ́ àti agbára le lórí; ẹni ó ń kiri ṣe oore, ó ń ṣe ìmúláradá gbogbo àwọn èṣù ń pọ́n lójú; nítorí Ọlọ́run pẹ̀rẹ̀.

39 "Àwa ni ẹlẹ́rìí gbogbo ohun ó ṣe, ilẹ̀ àwọn Júù, àti ni Jerusalẹmu. Ẹni wọ́n pa nípa gbígbékọ́ orí igi. 40 Òun ni Ọlọ́run dìde ni ọjọ́ kẹta ó fi i hàn gbangba. 41 í ṣe fún gbogbo ènìyàn ni o ri, ṣe fún àwa ti a jẹ́ ẹlẹ́rìí ti a ti ọwọ́ Ọlọ́run yàn tẹ̀, ti a a jẹ, ti a à mu lẹ́yìn ìgbà ti ó jíǹde kúrò nínú òkú. 42 Ó pàṣẹ fún wa láti wàásù fún àwọn ènìyàn, àti láti jẹ́rìí , òun ni a ti ọwọ́ Ọlọ́run yàn ṣe onídàájọ́ ààyè àti òkú. 43 Òun ni gbogbo àwọn wòlíì jẹ́rìí , ẹnikẹ́ni ti ó gbà á gbọ́ yóò ìdáríjì ̀ṣẹ̀ gbà nípa orúkọ rẹ̀."

44 Peteru ti ń sọ ̀rọ̀ wọ̀nyí lẹ́nu, ̀Mímọ́ gbogbo àwọn ti ó gbọ́ ̀rọ̀ náà. 45 Ẹnu àwọn onígbàgbọ́ ti a ti kọ nílà wọ́n Peteru , nítorí ti a tu ̀bùn ̀Mímọ́ sórí àwọn aláìkọlà pẹ̀. 46 Nítorí wọ́n gbọ́, wọ́n ń fọ onírúurú èdè, wọn yin Ọlọ́run lógo.

Nígbà náà ni Peteru dáhùn , 47 "Ẹnikẹ́ni ha ṣòfin pe, a bamitiisi àwọn wọ̀nyí wọ́n gba ̀Mímọ́ àwa?" 48 Ó pàṣẹ a bamitiisi wọn ni orúkọ Jesu Kristi. Nígbà náà ni wọ́n bẹ̀ ́ ó dúró ni ọjọ́ mélòó kan.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-