Pular para o conteúdo
Publicidade

Resultados da busca por "fé"

260 resultados encontrados

  1. Atos 16

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 16
    Mostrando versículos 5–30 de 40

    5Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ìjọ sì fẹsẹ̀múlẹ̀ ní ìgbàgbọ́, wọn sí ń pọ̀ sí i ní iye lójoojúmọ́.

    16Bí àwa tí n lọ sí ibi àdúrà náà, ọmọbìnrin kan tí o ní ẹ̀mí àfọ̀ṣẹ, pàdé wa, ẹni tí ó fi àfọ̀ṣẹ mú èrè púpọ̀ wá fún àwọn ọ̀gá rẹ̀.

    30Ó sì mú wọn jáde, ó ní, "Alàgbà, kín ni ki èmi ṣe ki n lè là?"

  2. Êxodo 7

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 7
    Mostrando versículos 3–13 de 25

    37.3: Ap 7.36.Ṣùgbọ́n èmi yóò sé Farao lọ́kàn le. Bí Mo tilẹ̀ ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ àmì àti ìyanu ni Ejibiti,

    7Mose jẹ́ ọmọ ọgọ́rin ọdún Aaroni sì jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́tàlélọ́gọ́rin ni ìgbà tí wọ́n bá Farao sọ̀rọ̀.

    13Síbẹ̀ ọkàn Farao sì yigbì, kò si fetí sí wọn gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti sọ.

  3. Romanos 5

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 5
    Mostrando versículos 2–5 de 21

    25.2: Ef 2.18; 3.12; Hb 10.19-20.Nípasẹ̀ ẹni tí àwa sì ti rí ọ̀nà gbà nípa ìgbàgbọ́ sí inú oore-ọ̀fẹ́ yìí nínú èyí tí àwa gbé dúró. Àwa sì ń yọ̀ nínú ìrètí ògo Ọlọ́run.

    4àti pé sùúrù ń ṣiṣẹ́ ìwà rere; àti pé ìwà rere ń ṣiṣẹ́ ìrètí.

    55.5: Sm 119.116; Ap 2.33; Fp 1.20.Ìrètí kì í sì í dójúti ni nítorí a ti dá ìfẹ́ Ọlọ́run sí wa lọ́kàn láti ọwọ́ Ẹ̀mí Mímọ́ tí a fi fún wa.

  4. 1 Crônicas 11

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 11
    Mostrando versículos 29–40 de 47

    29Sibekai ará Huṣati,láti ará Ahohi

    36Heferi ará Mekerati,Ahijah ará Peloni,

    40Ira ará Itri,Garebu ará Itri,

  5. Ezequiel 46

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 46
    Mostrando versículos 5–14 de 24

    5Ọrẹ ẹbọ jíjẹ tí a mú papọ̀ mọ́ àgbò gbọdọ̀ jẹ́ efa kan, ọrẹ ẹbọ jíjẹ tí a mú pẹ̀lú àwọn ọ̀dọ́-àgùntàn ni kí ó pò gẹ́gẹ́ bí ó bá ṣe fẹ́, papọ̀ mọ hínì òróró kan pẹ̀lú efa kọ̀ọ̀kan.

    7Yóò si pèsè ọrẹ ẹbọ jíjẹ efa fun ẹgbọrọ akọ màlúù, àti efa kan fun àgbò kan, àti fun àwọn ọ̀dọ́-àgùntàn gẹ́gẹ́ bi èyí ti ipá rẹ̀ ká, àti hínì òróró kan fún efa kan.

    14Ìwọ yóò sì máa pèsè ọrẹ ẹbọ jíjẹ pẹ̀lú rẹ̀ ní àràárọ̀, èyí yóò ni ìdámẹ́fà nínú efa àti ìdámẹ́fà nínú òróró hínì láti fi po ìyẹ̀fun. Gbígbé ọrẹ ẹbọ jíjẹ fún Olúwa jẹ́ ìlànà tí ó wà títí.

  6. Deuteronômio 5

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 5
    Mostrando versículos 2–20 de 33

    2Olúwa Ọlọ́run wa bá wa dá májẹ̀mú ní Horebu.

    4Olúwa bá a yín sọ̀rọ̀ lójúkojú láàrín iná lórí òkè.

    20Ìwọ kò gbọdọ̀ jẹ́rìí èké sí ẹnìkejì rẹ.

  7. Salmos 81

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 81
    Mostrando versículos 2–5 de 16

    2Ẹ mú orin mímọ́, kí ẹ sì mú ìlù wá,tẹ dùùrù dídùn pẹ̀lú ohun èlò orin mímọ́.

    3Ẹ fún ìpè ní oṣù tuntunàní nígbà tí a yàn;ní ọjọ́ àjọ wa tí ó ní ìrònú.

    5Ó fi múlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìlànà fún Josẹfunígbà tí ó la ilẹ̀ Ejibiti já.Níbi tí a ti gbọ́ èdè tí kò yé wa.

  8. Gênesis 5

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 5
    Mostrando versículos 6–25 de 32

    6Nígbà tí Seti pé àrùnlélọ́gọ́rùn-ún ọdún, ó bí Enoṣi.

    8Àpapọ̀ ọdún Seti sì jẹ́ ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rún ọdún ó lé méjìlá (912), ó sì kú.

    25Nígbà tí Metusela pé igba ọdún dín mẹ́tàlá ní o bí Lameki.

  9. Jó 14

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 14
    Mostrando versículos 1–14 de 22

    1"Ènìyàn tí a bí nínú obìnrin,ọlọ́jọ́ díẹ̀ ni, ó sì kún fún ìpọ́njú.

    4Ta ni ó lè mú ohun mímọ́ láti inú àìmọ́ jáde wá?Kò sí ẹnìkan!

    14Bí ènìyàn bá kú yóò sì tún yè bí?Gbogbo ọjọ́ ìgbà tí a là sílẹ̀fún mi ni èmi dúró dè, títí àmúdọ̀tún mi yóò fi dé.

  10. Provérbios 5

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 5
    Mostrando versículos 1–15 de 23

    1Ọmọ mi, fiyèsí ọgbọ́n mi,kí o sì dẹtí rẹ sí òye mi,

    2kí ìwọ sì lè ní ìṣọ́rakí ètè rẹ sì le pa ìmọ̀ mọ́.

    15Mu omi láti inú kànga tìrẹ,omi tí ń sàn láti inú kànga rẹ.

  11. Atos 2

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 2
    Mostrando versículos 8–44 de 47

    8Èéha sì tí ṣe ti olúkúlùkù wa fi ń gbọ́ bí wọ́n tí ń fi èdè sọ̀rọ̀?

    32Jesu náà yìí ni Ọlọ́run ti jí dìde sí ìyè, àwa pẹ̀lú sì jẹ́rìí sí èyí.

    442.44-45: Ap 4.32-35.Gbogbo àwọn tí ó sì gbàgbọ́ wà ni ibìkan, wọn ní ohun gbogbo sọ́kàn;

  12. Jeremias 17

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 17
    Mostrando versículos 9–17 de 27

    9Ọkàn ènìyàn kún fún ẹ̀tàn ju ohun gbogbo lọ,ó kọjá ohun tí a lè wòsàn.Ta ni èyí lè yé?

    12Ìtẹ́ ògo; ibi gíga láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ní ibi ilé mímọ́ wa.

    17Má ṣe di ìbẹ̀rù fún mi,ìwọ ni ààbò mi ní ọjọ́ ìpọ́njú.

  13. Êxodo 23

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 23
    Mostrando versículos 3–17 de 33

    323.3,6: Le 19.15.Bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ojúsàájú sí tálákà nínú ẹjọ́ rẹ̀.

    14 23.14-17: Ek 34.22-24; Le 23.1-44; De 16.1-17. "Ní ìgbà mẹ́ta ni ìwọ yóò ṣe àjọ fún mi nínú ọdún.

    17"Ní ìgbà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni àwọn ọkùnrin yín yóò máa wá fi ara hàn ní iwájú Olúwa Olódùmarè.

  14. Ezequiel 14

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 14
    Mostrando versículos 2–12 de 23

    2Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá,

    8Èmi yóò lòdì si irú ọkùnrin bẹ́ẹ̀ lọ́nà òdì, Èmi yóò sì fi i ṣe àmì àti òwe. Èmi yóò sì gé e kúrò láàrín àwọn ènìyàn mi. Nígbà náà, ẹ̀yin yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.

    12Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:

  15. Deuteronômio 24

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 24
    Mostrando versículos 2–18 de 22

    2tí ó bá di ìyàwó ọkùnrin mìíràn lẹ́yìn ìgbà tí ó kúrò nílé rẹ,

    8 24.8,9: Le 13–14. Ní ti ààrùn ẹ̀tẹ̀ kíyèsára láti máa ṣe gẹ́gẹ́ bí àwọn àlùfáà tí wọ́n jẹ́ ọmọ Lefi ti pàṣẹ fún ọ. O ní láti máa fi ìṣọ́ra tẹ̀lé ohun tí mo ti pàṣẹ fún wọn.

    18Rántí pé o jẹ́ ẹrú ní Ejibiti tí Olúwa Ọlọ́run rẹ sì gbà ọ́ níbẹ̀. Ìdí nìyí tí mo fi pa á láṣẹ fún ọ láti ṣe èyí.

  16. 1 Crônicas 6

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 6
    Mostrando versículos 4–48 de 81

    4Eleasari jẹ́ baba Finehasi,Finehasi baba Abiṣua

    16Àwọn ọmọ Lefi:Gerṣoni, Kohati àti Merari.

    48Àwọn Lefi ẹgbẹ́ wọn ni wọn yan àwọn iṣẹ́ yòókù ti àgọ́ fún, èyí tí í ṣe ilé Ọlọ́run.

  17. Salmos 49

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 49
    Mostrando versículos 6–20 de 20

    6àwọn tí o gbẹ́kẹ̀lé ọrọ̀ wọn,tí wọn sì ń ṣe ìlérí ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọrọ̀ wọn.

    13Èyí ni òtítọ́ àwọn ènìyàn tí ógbàgbọ́ nínú ara wọn,àti àwọn tí ń tẹ̀lé wọn,tí ó gba ọ̀rọ̀ wọn. Sela.

    20Ọkùnrin tí ó ní ọlá tí kò ní òye dàbí ẹranko tí ó ṣègbé.

  18. Romanos 2

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 2
    Mostrando versículos 6–29 de 29

    62.6: Mt 16.27; 1Kọ 3.8; 2Kọ 5.10; If 22.12.Ọlọ́run yóò san án fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀.

    28 2.28: Mt 3.9; Jh 8.39; Ro 9.6-7; Ga 6.15. Kì í ṣe èyí tí ó farahàn ní òde ni Júù, bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe èyí tí ó farahàn ní ara ni ìkọlà.

    292.29: 2Kọ 3.6; Fp 3.3; Kl 2.11; 1Pt 3.4.Ṣùgbọ́n Júù ti inú ni Júù, àti ìkọlà sì ni ti ọkàn nínú ẹ̀mí tí kì í ṣe ti àkọsílẹ̀, ìyìn ẹni tí kò sí lọ́dọ̀ ènìyàn, bí kò ṣe lọ́dọ̀ Ọlọ́run.

  19. Gênesis 37

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 37
    Mostrando versículos 5–15 de 36

    5Josẹfu lá àlá kan, nígbà tí ó sì sọ fún àwọn arákùnrin rẹ̀, wọ́n túbọ̀ kórìíra rẹ̀ sí i.

    6O wí fún wọn pé, "Ẹ fetí sí àlá tí mo lá,

    15ọkùnrin kan sì rí i tí ó ń rìn kiri inú pápá, ó sì bi í pé, "Kín ni ò ń wá?"

  20. Provérbios 13

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 13
    Mostrando versículos 4–19 de 25

    4Ọkàn ọ̀lẹ ń fẹ́, ṣùgbọ́n kò rí nǹkan kan,ṣùgbọ́n ọkàn àwọn ti kì í ṣe ọ̀lẹ rí ìtẹ́lọ́rùn.

    14Ìkọ́ni ọlọ́gbọ́n jẹ́ orísun ìyè,tí ń yí ènìyàn padà kúrò nínú ìdẹ̀kùn ikú.

    19Ìfẹ́ tí a mú ṣẹ dùn mọ́ ọkànṣùgbọ́n ìríra ni fún aṣiwèrè láti kúrò nínú ibi.

Léxico (correspondência exata) Semântico (correspondência relacionada) Versículos omitidos Contexto do capítulo