Pular para o conteúdo
Publicidade

Resultados da busca por "fé"

260 resultados encontrados

  1. Salmos 119

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 119
    Mostrando versículos 65–138 de 176

    65Ṣe rere sí ìránṣẹ́ rẹgẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ rẹ, Olúwa.

    125Èmi ni ìránṣẹ́ rẹ; ẹ fún mi ní òyekí èmi lè ní òye òfin rẹ

    138Òfin ti ìwọ gbé kalẹ̀ jẹ́ òdodo:wọ́n yẹ ni ìgbẹ́kẹ̀lé.

  2. Provérbios 1

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 1
    Mostrando versículos 2–20 de 33

    2Láti le ní ọgbọ́n àti ẹ̀kọ́,láti ní òye àwọn ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀.

    4láti fi òye fún onírẹ̀lẹ̀,ìmọ̀ àti ìṣọ́ra fún àwọn èwe.

    20 1.20,21: Òw 8.1-3. Ọgbọ́n kígbe sókè ní pópóó gbé ohùn rẹ̀ sókè láàrín ọjà;

  3. Jeremias 7

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 7
    Mostrando versículos 8–29 de 34

    8Ẹ wò ó, ẹ ń gba ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn tí kò níláárí gbọ́.

    15Èmi yóò tú kúrò ní iwájú mi gẹ́gẹ́ bí mo ti ṣe sí àwọn arákùnrin yín, àwọn ará Efraimu.’

    29" ‘Gé irun yín kí ẹ sì dàánù, pohùnréré ẹkún lórí òkè, nítorí Olúwa ti kọ ìran yìí tí ó wà lábẹ́ ìbínú rẹ̀ sílẹ̀.

  4. Êxodo 4

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 4
    Mostrando versículos 13–26 de 31

    13Mose dáhùn ó wí pé, "Olúwa jọ̀wọ́ rán ẹlòmíràn láti lọ ṣe iṣẹ́ yìí."

    20Mose mú ìyàwó rẹ̀ àti àwọn ọmọ rẹ̀, ó kó wọn lé orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ó sì bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò rẹ̀ padà sí Ejibiti. Ó sì mú ọ̀pá Ọlọ́run sí ọwọ́ rẹ̀.

    26Nítorí náà Olúwa yọ̀ǹda rẹ láti ìgbà tí ó ti wí pé, "Ẹlẹ́jẹ̀ ni ìwọ í ṣe." Èyí tó túmọ̀ sí ìkọlà abẹ́.

  5. Salmos 59

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 59
    Mostrando versículos 1–13 de 17

    1Gbà mí lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá à mi, Ọlọ́run;dáàbò bò mí kúrò lọ́dọ̀ àwọn tí ó dìde sí mi.

    10Ọlọ́run àánú mi ni yóò ṣáájú mi.Ọlọ́run yóò sì jẹ́ kí èmi rí ìfẹ́ mi lára àwọn ọ̀tá mi.Yóò sì jẹ́ kí n yọ ayọ̀ ìṣẹ́gun lórí ìfẹ́ àwọn ọ̀tá mi.

    13pa wọ́n run nínú ìbínú,run wọ́n di ìgbà tí wọn kò ní sí mọ́.Nígbà náà ni yóò di mí mọ̀ dé òpin ayépé Ọlọ́run jẹ ọba lórí Jakọbu. Sela.

  6. Provérbios 23

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 23
    Mostrando versículos 2–16 de 35

    2Ìwọ a sì fi ọ̀bẹ lé ara rẹ ní ọ̀fun,bí ìwọ bá jẹ́ òkúndùn ènìyàn.

    12Fi àyà sí ẹ̀kọ́,àti etí rẹ sí ọ̀rọ̀-ìmọ̀.

    16Inú mi yóò sì dùn nígbà tí ètè rẹ̀ bá ń sọ̀rọ̀ títọ́.

  7. Jeremias 44

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 44
    Mostrando versículos 1–16 de 30

    1Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wá nípa àwọn Júù tí ń gbé ní ìsàlẹ̀ Ejibiti ní Migdoli, Tafanesi àti Memfisi àti ní apá òkè Ejibiti:

    8Èéṣe tí ẹ fi mú mi bínú pẹ̀lú ohun tí ọwọ́ yín ṣe pẹ̀lú ẹbọ sísun sí àwọn òrìṣà Ejibiti, níbi tí ẹ wá láti máa gbé? Ẹ̀ ò pa ara yín run, ẹ̀ ó sì sọ ara yín di ẹni ìfiré àti ẹ̀gàn láàrín àwọn orílẹ̀-èdè ayé gbogbo.

    16"Wọn sì wí pé, àwa kò ní fetísílẹ̀ ọ̀rọ̀ tí o bá bá wa sọ ní orúkọ Olúwa.

  8. Salmos 144

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 144
    Mostrando versículos 3–8 de 15

    3Olúwa, kí ni ènìyàn tí ìwọ fi ń ṣàníyàn fún un,tàbí ọmọ ènìyàn tí ìwọ fi ń ronú nípa rẹ̀?

    4Ènìyàn rí bí èmi;ọjọ́ rẹ̀ rí bí òjìji tí ń kọjá lọ.

    8Ẹnu ẹni tí ó kún fún èkéẹni tí ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ jẹ́ ìrẹ́jẹ.

  9. Jeremias 22

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 22
    Mostrando versículos 2–29 de 30

    2‘Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ìwọ ọba Juda, tí ó jókòó ní ìtẹ́ Dafidi, ìwọ, àwọn ènìyàn rẹ àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ, tí ó wọlé láti ẹnu ibodè wọ̀nyí.

    14Ó wí pé, ‘Èmi ó kọ́ ààfin ńlá fún ara miàwọn yàrá òkè tí ó fẹ̀,ojú rèsé rẹ̀ yóò tóbi.’A ó sì fi igi kedari bò ó,a ó fi ohun aláwọ̀ pupa ṣe é ní ọ̀ṣọ́.

    27Ẹ̀yin kì yóò padà sí ilẹ̀ tí ẹ̀yin fẹ́ mọ́ láéláé."

    29Ìwọ ilẹ̀, ilẹ̀, ilẹ̀,gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa!

  10. Provérbios 11

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 11
    Mostrando versículos 17–30 de 31

    17Ènìyàn rere ń ṣe ara rẹ̀ lóoreṣùgbọ́n ènìyàn ìkà ń mú ìyọnu wá sórí ara rẹ̀.

    22Bí òrùka wúrà ní imú ẹlẹ́dẹ̀ni arẹwà obìnrin tí kò lọ́gbọ́n.

    30Èso òdodo ni igi ìyèẹni tí ó sì jèrè ọkàn jẹ́ ọlọ́gbọ́n.

  11. Salmos 97

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 97
    Mostrando versículos 1–5 de 12

    1Olúwa jẹ ọba, jẹ́ kí ayé kí ó yọ̀jẹ́ kí inú ọ̀pọ̀lọpọ̀ erékùṣù kí ó dùn.

    3Iná ń jó níwájú rẹ̀. Ó sì ń jó àwọn ọ̀tá rẹ̀ yíkákiri.

    5Òkè gíga yọ́ gẹ́gẹ́ bí ìda níwájú Olúwa,níwájú Olúwa gbogbo ayé.

  12. Jeremias 29

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 29
    Mostrando versículos 6–29 de 32

    6Ẹ ṣe ìgbéyàwó, kí ẹ sì bí ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin, ẹ gbé ìyàwó fún àwọn ọmọkùnrin yín, kí ẹ sì fi àwọn ọmọbìnrin yín fún ọkọ. Kí àwọn náà lè ní ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin. Ẹ máa pọ̀ sí i ní iye, ẹ kò gbọdọ̀ dínkù ní iye níbẹ̀ rárá.

    24Wí fún Ṣemaiah tí í ṣe Nehalami pé,

    29Sefaniah àlùfáà ka lẹ́tà náà sí etí ìgbọ́ Jeremiah tí í ṣe wòlíì.

  13. Provérbios 7

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 7
    Mostrando versículos 6–12 de 27

    6Ní ojú rèsé ilé è mimo wo ìta láti ojú rèsé.

    9Ní ìrọ̀lẹ́ bí oòrùn ṣe ń wọ̀,bí òkùnkùn ṣe ń bo ni lára.

    12bí ó ti ń já níhìn-ín ní ó ń já lọ́hùn úngbogbo orígun ni ó ti ń ba ní ibùba.)

  14. Salmos 46

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 46
    Mostrando versículos 1–10 de 11

    1Ọlọ́run ni ààbò àti agbára waó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ ní ìgbà ìpọ́njú.

    8Ẹ wá wo iṣẹ́ Olúwairú ahoro tí ó ṣe ní ayé.

    10Ẹ dúró jẹ́ẹ́, kí ẹ sì mọ̀ pé èmi ní Ọlọ́run.A ó gbé mi ga nínú àwọn orílẹ̀-èdè,a ó gbé mi ga ní ayé.

  15. Jeremias 32

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 32
    Mostrando versículos 6–27 de 44

    6Jeremiah wí pé, "Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:

    26Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wá pé:

    27"Èmi ni Olúwa Ọlọ́run gbogbo ẹran-ara. Ǹjẹ́ ohun kan ha a ṣòro fún mi bí?

  16. Salmos 108

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 108
    Mostrando versículos 2–12 de 13

    2Jí ohun èlò orin àti haapu!Èmi ó jí ní kùtùkùtù,

    10Ta ni yóò mú mi wá sí ìlú olódi?Ta ni yóò sìn mí wá sí Edomu?

    12Fún wa ní ìrànlọ́wọ́ nínú ìpọ́njú,nítorí ìrànlọ́wọ́ ènìyàn asán ni.

  17. Jeremias 23

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 23
    Mostrando versículos 9–26 de 40

    9Nípa ti àwọn wòlíì èké.Ọkàn mi ti bàjẹ́ nínú mi,gbogbo egungun mi ni ó wárìrì.Èmi dàbí ọ̀mùtí ènìyàn,bí ọkùnrin tí ọtí wáìnì ń pa;nítorí Olúwa àti àwọn ọ̀rọ̀ mímọ́ rẹ̀.

    23"Ǹjẹ́ Ọlọ́run tòsí nìkan ni Èmi bí?"ni Olúwa wí,"kì í sì í ṣe Ọlọ́run ọ̀nà jíjìn.

    26Títí di ìgbà wo ni èyí yóò fi máa tẹ̀síwájú ni ọkàn àwọn wòlíì èké wọ̀nyí tí wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ìtànjẹ ọkàn wọn?

  18. Salmos 41

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 41
    Mostrando versículos 4–13 de 13

    4Ní ti èmi, mo wí pé "Olúwa, ṣàánú fún mi;wò mí sàn, nítorí pé mo ti ṣẹ̀ sí ọ".

    9 41.9: Jh 13.18. Pàápàá, ọ̀rẹ́ mi tímọ́tímọ́, ẹni tí mo gbẹ́kẹ̀lé,ẹni tí ó ń jẹ nínú oúnjẹ mi,tí gbé gìgísẹ̀ rẹ̀ sókè sí mi.

    13Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,láé àti láéláé.Àmín àti Àmín.

  19. Salmos 102

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 102
    Mostrando versículos 6–15 de 28

    6Èmi dàbí ẹyẹ igún ní ijù:èmi dàbí òwìwí ibi ahoro.

    7Èmi dìde; èmi dàbí ẹyẹ lórí ilé.

    9Èmi jẹ eérú gẹ́gẹ́ bí oúnjẹ mi, èmi sì da ohun mímu mi pọ̀ pẹ̀lú omijé.

    15Àwọn kèrí yóò bẹ̀rù orúkọ Olúwa,gbogbo ọba ayé yóò máa bẹ̀rù ògo rẹ.

  20. Salmos 68

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 68
    Mostrando versículos 1–19 de 35

    1Kí Ọlọ́run kí ó dìde, kí àwọn ọ̀tá rẹ̀ kí ó fọ́nká;kí àwọn ọ̀tá rẹ̀ kí ó sá níwájú rẹ̀.

    10Àwọn ènìyàn rẹ tẹ̀dó síbẹ̀nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìní rẹ, Ọlọ́run, ìwọ pèsè fún àwọn aláìní.

    19Olùbùkún ni Olúwa,Ọlọ́run Olùgbàlà wa,ẹni tí ó ń fi ojoojúmọ́ gba ẹrù wa rù. Sela.

Léxico (correspondência exata) Semântico (correspondência relacionada) Versículos omitidos Contexto do capítulo