Pular para o conteúdo
Publicidade

Resultados da busca por "salvação"

50 resultados encontrados

  1. Salmos 89

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 89
    Mostrando versículos 37–52 de 52

    37 89.37: If 1.5; 3.14. A ó fi múlẹ̀ títí láé bí òṣùpá,àti bi ẹlẹ́rìí òtítọ́ ni ọ̀run." Sela.

    48Ta ni yóò wà láààyè tí kò ní rí ikú rẹ̀?Ta ló lè sá kúrò nínú agbára isà òkú?

    52Olùbùkún ní Olúwa títí láé.Àmín àti Àmín.

  2. Neemias 12

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 12
    Mostrando versículos 3–34 de 47

    3Ṣekaniah, Rehumu, Meremoti,

    6Ṣemaiah, Joiaribu, Jedaiah,

    34Juda, Benjamini, Ṣemaiah, Jeremiah,

  3. Êxodo 26

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 26
    Mostrando versículos 23–34 de 37

    23kí o sì ṣe pákó méjì fún igun ní ìhà ẹ̀yìn.

    30"Gbé àgọ́ náà ró gẹ́gẹ́ bí àpẹẹrẹ tí a fihàn ọ́ lórí òkè.

    34Fi ìtẹ́ àánú bo àpótí ẹ̀rí náà ni Ibi Mímọ́ Jùlọ.

  4. 1 Crônicas 11

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 11
    Mostrando versículos 29–41 de 47

    29Sibekai ará Huṣati,láti ará Ahohi

    40Ira ará Itri,Garebu ará Itri,

    41Uriah ará HitiSabadi ọmọ Ahlai.

  5. Salmos 46

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 46
    Mostrando versículos 1–5 de 11

    1Ọlọ́run ni ààbò àti agbára waó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ ní ìgbà ìpọ́njú.

    3Tí omi rẹ̀ tilẹ̀ ń hó tí ó sì ń mìtí àwọn òkè ńlá tilẹ̀ ń mì pẹ̀lú ọwọ́ agbára rẹ̀. Sela.

    5Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ̀, kò ní yẹ̀:Ọlọ́run yóò ràn án lọ́wọ́ ní kùtùkùtù òwúrọ̀.

  6. Êxodo 28

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 28
    Mostrando versículos 7–24 de 43

    7Kí ó ni aṣọ èjìká méjì tí a so mọ́ igun rẹ̀ méjèèjì, kí a lè so ó pọ̀.

    18ní ẹsẹ̀ kejì turikuose, emeradi, safire, àti diamọndi;

    24Ìwọ yóò so ẹ̀wọ̀n wúrà méjèèjì mọ́ òrùka ní igun ìgbàyà náà,

  7. Provérbios 25

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 25
    Mostrando versículos 4–28 de 28

    4Mú ìdàrọ́ kúrò lára fàdákàohun èlò yóò sì jáde fún alágbẹ̀dẹ fàdákà.

    19Bí eyín tí ó bàjẹ́ tàbí ẹsẹ̀ tí ó rọni ìgbẹ́kẹ̀lé lórí aláìṣòótọ́ ní àsìkò ìdààmú.

    28Bí ìlú tí odi rẹ̀ ti wó lulẹ̀ni ènìyàn tí kò le kó ara rẹ̀ ní ìjánu.

  8. Neemias 11

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 11
    Mostrando versículos 8–29 de 36

    8àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, Gabbai àti Sallai jẹ́ ọ̀rìndínlẹ́gbẹ̀rún ó lé mẹ́jọ (928) ọkùnrin.

    26Ní Jeṣua, ní Molada, ní Beti-Peleti

    29ní Ẹni-Rimoni, ní Sora, ní Jarmatu,

  9. Salmos 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 1–8 de 8

    1Olúwa, báwo ni àwọn ọ̀tá mi ṣe pọ̀ tó báyìí!Báwo ni àwọn ti ó dìde sí mi ṣe pọ̀ tó!

    4Olúwa ni mo kígbe sókè sí,ó sì dá mi lóhùn láti orí òkè mímọ́ rẹ̀ wá. Sela.

    8Láti ọ̀dọ̀ Olúwa ni ìgbàlà ti wá.Kí ìbùkún rẹ wà lórí àwọn ènìyàn rẹ. Sela.

  10. Salmos 90

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 90
    Mostrando versículos 3–13 de 17

    3Ìwọ yí ènìyàn padà sí erùpẹ̀,wí pé, "Padà sí erùpẹ̀, ìwọ ọmọ ènìyàn."

    6Lóòtítọ́, ní òwúrọ̀, ó yọ tuntunní àṣálẹ́ ni yóò gbẹ, tí yóò sì rẹ̀ dànù.

    13Yípadà, Olúwa! Yóò ti pẹ́ tó?Ṣàánú fún àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ.

Léxico (correspondência exata) Semântico (correspondência relacionada) Versículos omitidos Contexto do capítulo