Pular para o conteúdo
Publicidade

Resultados da busca por "salvação"

45 resultados encontrados

  1. João 11

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 11
    Mostrando versículos 18–35 de 57

    18ǹjẹ́ Betani súnmọ́ Jerusalẹmu tó ibùsọ̀ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún.

    29Nígbà tí ó gbọ́, ó dìde lọ́gán, ó sì wá sọ́dọ̀ rẹ̀.

    35 11.35: Lk 19.41. Jesu sọkún.

  2. Provérbios 13

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 13
    Mostrando versículos 9–19 de 25

    9Ìmọ́lẹ̀ olódodo tàn roro,ṣùgbọ́n fìtílà ènìyàn búburú ni a pa kú.

    14Ìkọ́ni ọlọ́gbọ́n jẹ́ orísun ìyè,tí ń yí ènìyàn padà kúrò nínú ìdẹ̀kùn ikú.

    19Ìfẹ́ tí a mú ṣẹ dùn mọ́ ọkànṣùgbọ́n ìríra ni fún aṣiwèrè láti kúrò nínú ibi.

  3. Salmos 108

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 108
    Mostrando versículos 2–12 de 13

    2Jí ohun èlò orin àti haapu!Èmi ó jí ní kùtùkùtù,

    10Ta ni yóò mú mi wá sí ìlú olódi?Ta ni yóò sìn mí wá sí Edomu?

    12Fún wa ní ìrànlọ́wọ́ nínú ìpọ́njú,nítorí ìrànlọ́wọ́ ènìyàn asán ni.

  4. Marcos 4

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 4
    Mostrando versículos 14–18 de 41

    14Afúnrúgbìn ń fúnrúgbìn ọ̀rọ̀ náà.

    16Bákan náà, àwọn tí ó bọ́ sórí àpáta, ni àwọn ènìyàn tí wọ́n fi ayọ̀ gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run.

    18Àwọn tí ó bọ́ sáàrín ẹ̀gún ni àwọn tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ náà, tí wọn sì gbà á.

  5. Mateus 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 8–16 de 17

    8Ẹ so èso tí ó yẹ fún ìrònúpìwàdà.

    11"Èmi fi omi bamitiisi yín fún ìrònúpìwàdà. Ṣùgbọ́n lẹ́yìn mi ẹnìkan tí ó pọ̀jù mí lọ ń bọ̀, bàtà ẹni tí èmi kò tó gbé. Òun ni yóò fi Ẹ̀mí Mímọ́ àti iná bamitiisi yín.

    16Bí ó si tí ṣe ìtẹ̀bọmi fún Jesu tán, Ó jáde láti inú omi. Ní àkókò náà ọ̀run ṣí sílẹ̀ fún un, Ó sì rí Ẹ̀mí Ọlọ́run ń sọ̀kalẹ̀ bí àdàbà, ó sì bà lé e.

  6. Salmos 60

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 60
    Mostrando versículos 9–12 de 12

    9Ta ni yóò mú mi wá sí ìlú olódi nì?Ta ni yóò tọ́ mí lọ sí Edomu?

    11Fún wa ní ìrànlọ́wọ́ lórí àwọn ọ̀tá,nítorí asán ni ìrànlọ́wọ́ ènìyàn.

    12Nípa Ọlọ́run ni a óò ní ìṣẹ́gun,yóò sì tẹ àwọn ọ̀tá wa mọ́lẹ̀.

  7. Esdras 2

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 2
    Mostrando versículos 4–49 de 70

    4Ṣefatia jẹ́ òjìdínnírinwó ó lé méjìlá (372)

    8Sattu jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rún ó lé márùn-ún (945)

    49Ussa, Pasea, Besai,

  8. 1 Crônicas 1

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 1
    Mostrando versículos 18–24 de 54

    18Arfakṣadi sì bí Ṣela,Ṣela sì bí Eberi.

    22Ebali, Abimaeli, Ṣeba.

    24Ṣemu, Arfakṣadi, Ṣela,

  9. Provérbios 26

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 26
    Mostrando versículos 6–22 de 28

    6Bí ìgbà tí ènìyàn gé ẹsẹ̀ ara rẹ̀ tàbí mú ìwà ipáni kí a ránṣẹ́ nípasẹ̀ aṣiwèrè.

    18Bí i asínwín ti ń juọfà àti ọfà tí ń ṣe kú pa ni

    22Ọ̀rọ̀ ẹni tí ń sọ̀rọ̀ ẹ̀yìn dàbí àṣàyàn òkèlèwọ́n a sì wọ ìsàlẹ̀ inú lọ.

  10. Jó 28

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 28
    Mostrando versículos 3–22 de 28

    3Ènìyàn ni ó fi òpin si òkùnkùn,ó sì ṣe àwárí ìṣúraláti inú òjìji ikú sí ìhà gbogbo.

    6òkúta ibẹ̀ ni ibi òkúta safire,o sì ní erùpẹ̀ wúrà.

    22Ibi ìparun àti ikú wí pé,àwa ti fi etí wa gbúròó rẹ̀.

  11. Esdras 10

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 10
    Mostrando versículos 37–41 de 44

    37Mattaniah, Mattenai àti Jaasu.

    39Ṣelemiah, Natani, Adaiah,

    41Asareeli, Ṣelemiah, Ṣemariah,

  12. Filipenses 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 11–16 de 21

    11nípasẹ̀ bẹ́ẹ̀ kí èmi lè ní àjíǹde kúrò nínú òkú.

    14Èmi ń lépa láti dé òpin eré ìje náà fún èrè ìpè gíga Ọlọ́run nínú Kristi Jesu.

    16Kìkì pé, ki a ma gbe ìgbé ayé gẹ́gẹ́ bi èyí ti a ri gba.

  13. Neemias 10

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 10
    Mostrando versículos 3–23 de 39

    3Paṣuri, Amariah, Malkiah,

    20Magpiaṣi, Meṣullamu, Hesiri

    23Hosea, Hananiah, Haṣubu,

  14. 1 Crônicas 8

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 8
    Mostrando versículos 4–26 de 40

    4Abiṣua, Naamani, Ahoa,

    19Jakimu, Sikri, Sabdi,

    26Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah

  15. Jó 8

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 8
    Mostrando versículos 3–17 de 22

    3Ọlọ́run a ha máa yí ìdájọ́ po bí?Tàbí Olódùmarè a máa gbé ẹ̀bi fún aláre?

    14Àbá ẹni tí a ó kèé kúrò,àti ìgbẹ́kẹ̀lé ẹni tí ó dàbí ilé aláǹtakùn.

    17Gbòǹgbò rẹ̀ ta yí ebè ká,ó sì wó ibi òkúta wọ̀n-ọn-nì.

  16. Sofonias 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 1–10 de 20

    1Ègbé ni fún ìlú aninilára,ọlọ̀tẹ̀ àti aláìmọ́.

    5Olúwa ni àárín rẹ̀ jẹ́ olódodo;kì yóò ṣe ohun tí kò tọ̀nà.Àràárọ̀ ni ó máa ń mú ìdájọ́ rẹ̀ wá sí ìmọ́lẹ̀,kì í sì kùnà ní gbogbo ọjọ́ tuntun,síbẹ̀ àwọn aláìṣòótọ́ kò mọ ìtìjú.

    10Láti òkè odò Etiopia,àwọn olùjọsìn mi, àwọn ènìyàn mi tí ó ti fọ́nká,yóò mú ọrẹ wá fún mi.

  17. Lucas 24

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 24
    Mostrando versículos 2–51 de 53

    2Òkúta ti yí kúrò ní ẹnu ibojì.

    28 24.28: Mk 6.48. Wọ́n sì súnmọ́ ìletò tí wọ́n ń lọ, ó sì ṣe bí ẹni pé yóò lọ sí iwájú.

    5124.51: Ap 1.9-11.Ó sì ṣe, bí ó ti ń súre fún wọn, ó yà kúrò lọ́dọ̀ wọn, a sì gbé e lọ sí ọ̀run.

  18. Êxodo 20

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 20
    Mostrando versículos 8–14 de 26

    8 20.8: Ek 23.12; 31.12-17; 34.21; 35.2,3; Le 19.3; De 5.12-15. Rántí ọjọ́ ìsinmi láti yà á sí mímọ́.

    13 20.13: Gẹ 9.6; Ek 21.12; Le 24.17; De 5.17; Mt 5.21; Jk 2.11. 20.13-17: Ro 13.9. Ìwọ kò gbọdọ̀ pànìyàn.

    14 20.14: Le 20.10; De 5.18; Mt 5.27; Ro 7.7. Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe panṣágà.

  19. Neemias 7

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 7
    Mostrando versículos 9–48 de 73

    9Ṣefatia jẹ́ òjìdínnírinwó ó lé méjìlá (372)

    13Sattu jẹ́ òjìlélẹ́gbẹ̀rin ó lé márùn-ún (845)

    48Lebana, Hagaba, Ṣalmai,

  20. Isaías 32

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 32
    Mostrando versículos 8–15 de 20

    8Ṣùgbọ́n ọlọ́lá ènìyàn a máa pète ohun ńláàti nípa èrò rere ni yóò dúró.

    12Ẹ lu ọmú yín fún pápá ìgbádùn náà,fún àwọn àjàrà eléso

    15títí a ó fi tú Ẹ̀mí sí wa lórí láti òkè wá,àti ti aṣálẹ̀ tí yóò dí pápá oko ọlọ́ràáàti tí pápá ọlọ́ràá yóò dàbí ẹgàn.

Léxico (correspondência exata) Semântico (correspondência relacionada) Versículos omitidos Contexto do capítulo