18ǹjẹ́ Betani súnmọ́ Jerusalẹmu tó ibùsọ̀ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún.
29Nígbà tí ó gbọ́, ó dìde lọ́gán, ó sì wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
35 11.35: Lk 19.41. Jesu sọkún.
45 resultados encontrados
18ǹjẹ́ Betani súnmọ́ Jerusalẹmu tó ibùsọ̀ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún.
29Nígbà tí ó gbọ́, ó dìde lọ́gán, ó sì wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
35 11.35: Lk 19.41. Jesu sọkún.
9Ìmọ́lẹ̀ olódodo tàn roro,ṣùgbọ́n fìtílà ènìyàn búburú ni a pa kú.
14Ìkọ́ni ọlọ́gbọ́n jẹ́ orísun ìyè,tí ń yí ènìyàn padà kúrò nínú ìdẹ̀kùn ikú.
19Ìfẹ́ tí a mú ṣẹ dùn mọ́ ọkànṣùgbọ́n ìríra ni fún aṣiwèrè láti kúrò nínú ibi.
2Jí ohun èlò orin àti haapu!Èmi ó jí ní kùtùkùtù,
10Ta ni yóò mú mi wá sí ìlú olódi?Ta ni yóò sìn mí wá sí Edomu?
12Fún wa ní ìrànlọ́wọ́ nínú ìpọ́njú,nítorí ìrànlọ́wọ́ ènìyàn asán ni.
14Afúnrúgbìn ń fúnrúgbìn ọ̀rọ̀ náà.
16Bákan náà, àwọn tí ó bọ́ sórí àpáta, ni àwọn ènìyàn tí wọ́n fi ayọ̀ gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run.
18Àwọn tí ó bọ́ sáàrín ẹ̀gún ni àwọn tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ náà, tí wọn sì gbà á.
8Ẹ so èso tí ó yẹ fún ìrònúpìwàdà.
11"Èmi fi omi bamitiisi yín fún ìrònúpìwàdà. Ṣùgbọ́n lẹ́yìn mi ẹnìkan tí ó pọ̀jù mí lọ ń bọ̀, bàtà ẹni tí èmi kò tó gbé. Òun ni yóò fi Ẹ̀mí Mímọ́ àti iná bamitiisi yín.
16Bí ó si tí ṣe ìtẹ̀bọmi fún Jesu tán, Ó jáde láti inú omi. Ní àkókò náà ọ̀run ṣí sílẹ̀ fún un, Ó sì rí Ẹ̀mí Ọlọ́run ń sọ̀kalẹ̀ bí àdàbà, ó sì bà lé e.
9Ta ni yóò mú mi wá sí ìlú olódi nì?Ta ni yóò tọ́ mí lọ sí Edomu?
11Fún wa ní ìrànlọ́wọ́ lórí àwọn ọ̀tá,nítorí asán ni ìrànlọ́wọ́ ènìyàn.
12Nípa Ọlọ́run ni a óò ní ìṣẹ́gun,yóò sì tẹ àwọn ọ̀tá wa mọ́lẹ̀.
4Ṣefatia jẹ́ òjìdínnírinwó ó lé méjìlá (372)
8Sattu jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rún ó lé márùn-ún (945)
49Ussa, Pasea, Besai,
18Arfakṣadi sì bí Ṣela,Ṣela sì bí Eberi.
22Ebali, Abimaeli, Ṣeba.
24Ṣemu, Arfakṣadi, Ṣela,
6Bí ìgbà tí ènìyàn gé ẹsẹ̀ ara rẹ̀ tàbí mú ìwà ipáni kí a ránṣẹ́ nípasẹ̀ aṣiwèrè.
18Bí i asínwín ti ń juọfà àti ọfà tí ń ṣe kú pa ni
22Ọ̀rọ̀ ẹni tí ń sọ̀rọ̀ ẹ̀yìn dàbí àṣàyàn òkèlèwọ́n a sì wọ ìsàlẹ̀ inú lọ.
3Ènìyàn ni ó fi òpin si òkùnkùn,ó sì ṣe àwárí ìṣúraláti inú òjìji ikú sí ìhà gbogbo.
6òkúta ibẹ̀ ni ibi òkúta safire,o sì ní erùpẹ̀ wúrà.
22Ibi ìparun àti ikú wí pé,àwa ti fi etí wa gbúròó rẹ̀.
37Mattaniah, Mattenai àti Jaasu.
39Ṣelemiah, Natani, Adaiah,
41Asareeli, Ṣelemiah, Ṣemariah,
11nípasẹ̀ bẹ́ẹ̀ kí èmi lè ní àjíǹde kúrò nínú òkú.
14Èmi ń lépa láti dé òpin eré ìje náà fún èrè ìpè gíga Ọlọ́run nínú Kristi Jesu.
16Kìkì pé, ki a ma gbe ìgbé ayé gẹ́gẹ́ bi èyí ti a ri gba.
3Paṣuri, Amariah, Malkiah,
20Magpiaṣi, Meṣullamu, Hesiri
23Hosea, Hananiah, Haṣubu,
4Abiṣua, Naamani, Ahoa,
19Jakimu, Sikri, Sabdi,
26Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
3Ọlọ́run a ha máa yí ìdájọ́ po bí?Tàbí Olódùmarè a máa gbé ẹ̀bi fún aláre?
14Àbá ẹni tí a ó kèé kúrò,àti ìgbẹ́kẹ̀lé ẹni tí ó dàbí ilé aláǹtakùn.
17Gbòǹgbò rẹ̀ ta yí ebè ká,ó sì wó ibi òkúta wọ̀n-ọn-nì.
1Ègbé ni fún ìlú aninilára,ọlọ̀tẹ̀ àti aláìmọ́.
5Olúwa ni àárín rẹ̀ jẹ́ olódodo;kì yóò ṣe ohun tí kò tọ̀nà.Àràárọ̀ ni ó máa ń mú ìdájọ́ rẹ̀ wá sí ìmọ́lẹ̀,kì í sì kùnà ní gbogbo ọjọ́ tuntun,síbẹ̀ àwọn aláìṣòótọ́ kò mọ ìtìjú.
10Láti òkè odò Etiopia,àwọn olùjọsìn mi, àwọn ènìyàn mi tí ó ti fọ́nká,yóò mú ọrẹ wá fún mi.
2Òkúta ti yí kúrò ní ẹnu ibojì.
28 24.28: Mk 6.48. Wọ́n sì súnmọ́ ìletò tí wọ́n ń lọ, ó sì ṣe bí ẹni pé yóò lọ sí iwájú.
5124.51: Ap 1.9-11.Ó sì ṣe, bí ó ti ń súre fún wọn, ó yà kúrò lọ́dọ̀ wọn, a sì gbé e lọ sí ọ̀run.
8 20.8: Ek 23.12; 31.12-17; 34.21; 35.2,3; Le 19.3; De 5.12-15. Rántí ọjọ́ ìsinmi láti yà á sí mímọ́.
13 20.13: Gẹ 9.6; Ek 21.12; Le 24.17; De 5.17; Mt 5.21; Jk 2.11. 20.13-17: Ro 13.9. Ìwọ kò gbọdọ̀ pànìyàn.
14 20.14: Le 20.10; De 5.18; Mt 5.27; Ro 7.7. Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe panṣágà.
9Ṣefatia jẹ́ òjìdínnírinwó ó lé méjìlá (372)
13Sattu jẹ́ òjìlélẹ́gbẹ̀rin ó lé márùn-ún (845)
48Lebana, Hagaba, Ṣalmai,
8Ṣùgbọ́n ọlọ́lá ènìyàn a máa pète ohun ńláàti nípa èrò rere ni yóò dúró.
12Ẹ lu ọmú yín fún pápá ìgbádùn náà,fún àwọn àjàrà eléso
15títí a ó fi tú Ẹ̀mí sí wa lórí láti òkè wá,àti ti aṣálẹ̀ tí yóò dí pápá oko ọlọ́ràáàti tí pápá ọlọ́ràá yóò dàbí ẹgàn.