Publicidade

Cânticos 1

1 Orin, àwọn orin í ṣe orin Solomoni.

Olólùfẹ́

2 Fi ìfẹnukonu ìfẹ́ ẹnu,

nítorí ìfẹ́ rẹ dára ju ọtí wáìnì lọ.

3 Òórùn ìkunra rẹ fanimọ́ra.

Orúkọ rẹ ìkunra a jáde

abájọ àwọn wúńdíá fi fẹ́ .

4 lọ pẹ̀rẹ, a lọ kíákíá

ọba ti mi sínú yàrá rẹ̀.

̀rẹ́

Àwa yọ̀ inú wa dùn ;

a gbé ìfẹ́ rẹ ga ju ọtí wáìnì lọ.

Olólùfẹ́

Wọ́n fẹ́ nítòótọ́!

5 Èmi dúdú mo ẹwà.

̀yin ọmọbìnrin Jerusalẹmu

dúdú àgọ́ ìlú Kedari,

aṣọ títa ti Solomoni.

6 ṣe nítorí mo dúdú,

nítorí oòrùn mi dúdú,

ọmọkùnrin ìyá mi bínú mi

ó fi ṣe olùtọ́ọgbà àjàrà;

ọgbà àjàrà tèmi ni èmi tọ́.

7 fún mi, ìwọ ẹni ọkàn fẹ́,

níbo ni ìwọ ń da agbo ẹran lọ.

Níbi ìwọ agbo ẹran rẹ sinmi ̀sán,

ni ìdí èmi yóò fi jẹ́ obìnrin asán

̀agbo ẹran àwọn ̀rẹ́ rẹ.

̀rẹ́

8 ìwọ mọ̀,

ìwọ arẹwà jùlọ nínú àwọn obìnrin.

̀agbo ẹran rìn lọ,

o bọ́ àwọn ọmọ ewúrẹ́ rẹ.

̀àgọ́ àwọn olùṣọ́-àgùntàn.

Olùfẹ́

9 Olùfẹ́ mi,

mo fi ́ ẹṣin mi nínú kẹ̀kẹ́ Farao.

10 ̀rẹ̀kẹ́ rẹ dára ohun ̀ṣọ́,

ọrùn rẹ yẹ ̀ṣọ́ ìlẹ̀kẹ̀.

11 A ó fi wúrà ṣe òrùka etí fún ,

a ó fi fàdákà ṣe ìlẹ̀kẹ̀.

Olólùfẹ́

12 Nígbà ọba orí ìjókòó rẹ̀,

òróró ìkunra mi òórùn jáde.

13 Ìdì òjìá ni olùfẹ́ mi jẹ mi,

òun ó sinmi àárín ọmú mi.

14 ìdì ìtànná Henina ni olùfẹ́ mi mi

láti inú ọgbà àjàrà ti En-Gedi.

Olùfẹ́

15 Báwo ni o ti lẹ́, olólùfẹ́ mi!

Háà, báwo ni o ṣe lẹ́!

Ìwọ ojú ẹyẹlé.

Olólùfẹ́

16 Báwo ni o ṣe dára , olùfẹ́ mi!

Háà, báwo ni o ṣe wu ni!

Ibùsùn wa ìtura.

Olùfẹ́

17 Ìtànṣán ilé wa jẹ́ ti igi kedari

ẹkẹ́ ilé wa jẹ́ ti igi firi.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-