Publicidade

Lucas 22

Judasi gbà láti da Jesu

1 Àjọ ọdún àìwúkàrà à ń Ìrékọjá fẹ́́rẹ́. 2 Àti àwọn olórí àlùfáà, àti àwọn akọ̀ń ̀wọn ìbá gbà pa á; nítorí wọn ń bẹ̀àwọn ènìyàn. 3 Satani wọ inú Judasi, à ń Iskariotu, ̀kan nínú àwọn méjìlá. 4 Ó ̀rẹ̀ pọ̀n, ó lọ láti àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olórí ̀ṣọ́ gbèrò pọ̀, òun yóò fi í wọn lọ́wọ́. 5 Wọ́n yọ̀, wọ́n a májẹ̀láti fún un owó. 6 Ó gbà; ó ń àkókò ó wọ̀, láti fi í wọn lọ́wọ́ láìsí ariwo.

Oúnjẹ alẹ́ Olúwa

7 Ọjọ́ àìwúkàrà , nígbà wọ́n láti pa ̀dọ́-àgùntàn ìrékọjá fún ìrúbọ. 8 Ó rán Peteru àti Johanu, , "lọ pèsè ìrékọjá fún wa, àwa ó jẹ."

9 Wọ́n fún un , "Níbo ni ìwọ ń fẹ́ á pèsè sílẹ̀?"

10 Ó fún wọn , "Kíyèsi i, nígbà ̀yin ń wọ ìlú lọ, ọkùnrin kan ó ru ìkòkò omi yóò pàdé yín, a lọ ilé ó wọ̀, 11 fún baálé ilé náà , Olùkọ́ fún , níbo ni gbàngàn àpèjẹ náà gbé , níbi èmi ó gbé jẹ ìrékọjá pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mi? 12 Òun ó fi gbàngàn ńlá kan lókè ilé hàn yín, a ṣe lọ́ṣọ̀́, níbẹ̀ ni ̀yin pèsè sílẹ̀."

13 Wọ́n lọ wọ́n a gẹ́gẹ́ ó sọ fún wọn, wọ́n pèsè ìrékọjá sílẹ̀.

14 Nígbà àkókò , ó jókòó àti àwọn aposteli pẹ̀rẹ̀. 15 Ó fún wọn , "Tinútinú ni èmi fẹ́ fi yín jẹ ìrékọjá yìí, èmi jìyà. 16 Nítorí mo fún yín, Èmi yóò jẹ nínú rẹ̀ mọ́, títí a ó fi un ṣẹ ìjọba Ọlọ́run."

17 Ó gba ago, nígbà ó ti dúpẹ́, ó , "Gba èyí, pín in láàrín ara yín. 18 Nítorí mo fún yín, Èmi yóò mu nínú èso àjàrà mọ́, títí ìjọba Ọlọ́run yóò fi ."

19 Ó àkàrà, nígbà ó ti dúpẹ́ ó ú, ó fi fún wọn, ó , "Èyí ni ara a fi fún yín, máa ṣe èyí ìrántí mi."

20 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ lẹ́yìn oúnjẹ alẹ́, ó ago wáìnì, ó , "Ago yìí ni májẹ̀tuntun nínú ̀jẹ̀ mi, a ta sílẹ̀ fún yín. 21 Ṣùgbọ́n kíyèsi i, ọwọ́ ẹni yóò fi hàn pẹ̀mi lórí tábìlì. 22 Ọmọ Ènìyàn ń lọ nítòótọ́ a pinnu rẹ̀, ṣùgbọ́n ègbé ni fún ọkùnrin náà nípasẹ̀ ẹni a gbé ti fi í hàn." 23 Wọ́n bẹ̀rẹ̀ béèrè láàrín ara wọn, ta ni nínú wọn yóò ṣe nǹkan yìí.

24 Ìjà kan ń bẹ láàrín wọn, ti ẹni a olórí nínú wọn. 25 Ó fún wọn , "Àwọn ọba aláìkọlà a máa fẹlá lórí wọn, a máa pe àwọn aláṣẹ wọn olóore. 26 Ṣùgbọ́n ̀yin yóò bẹ́̀; ṣùgbọ́n ẹni ó ba pọ̀nínú yín ó jẹ́ ẹni o kéré ju àbúrò; ẹni ó ṣe olórí, ẹni ń ṣe ìránṣẹ́. 27 Nítorí ta ni ó pọ̀, ẹni ó jókòó oúnjẹ, tàbí ẹni ó ń ṣe ìránṣẹ́. Ẹni ó jókòó ti oúnjẹ kọ́ ? Ṣùgbọ́n èmi ń bẹ láàrín yín ẹni ń ṣe ìránṣẹ́. 28 ̀yin ni àwọn ó ti dúró nínú ìdánwò mi. 29 Mo yan ìjọba fún yín, gẹ́gẹ́ Baba mi ti yàn fún mi. 30 ̀yin máa jẹ, ̀yin máa mu lórí tábìlì mi ìjọba mi, ̀yin jókòó lórí ìtẹ́, àti ̀yin máa ṣe ìdájọ́ fún àwọn ̀Israẹli méjìlá."

31 Olúwa , "Simoni, Simoni, ó, Satani fẹ́ láti gbà ́, ó ́ alikama. 32 Ṣùgbọ́n mo ti gbàdúrà fún , ìgbàgbọ́ rẹ ṣe yẹ̀; àti ìwọ nígbà ìwọ padà bọ̀ sípò, àwọn arákùnrin rẹ lọ́kàn le."

33 Ó fún un , "Olúwa, mo múra tán láti lọ sínú túbú, àti ikú."

34 Ó , "Mo fún , Peteru, àkùkọ yóò kọ lónìí ìwọ ó fi sẹ́ mi lẹ́̀mẹ́ta , ìwọ mọ̀ ."

35 Ó fún wọn , "Nígbà mo rán yín lọ láìní àpò-owó, àti àpò, àti bàtà, ̀ohun kan yín ?"

Wọ́n , "Rárá!"

36 Nígbà náà ni ó fún wọn , "Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ẹni ó àpò-owó ó un, àti àpò pẹ̀; ẹni idà, ó ta aṣọ rẹ̀, ó fi ra ̀kan. 37 Nítorí mo fún yín , Èyí a ti kọ̀rẹ̀ ṣe ó ṣẹ lára mi, a á mọ́ àwọn arúfin.Nítorí àwọn ohun wọ̀nyí nípa ti èmi yóò ìmúṣẹ." a á mọ́ àwọn alárékọjá.

38 Wọ́n , "Olúwa, ó, idà méjì ń bẹ níhìn-ín yìí!"

Ó fún wọn , "Ó ."

Jesu gbàdúrà lórí òkè olifi

39 Ó jáde, ó lọ ìṣe rẹ̀ òkè olifi, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tọ̀ ́ lẹ́yìn. 40 Nígbà ó níbẹ̀, ó fún wọn , "máa gbàdúrà, ̀yin ṣe bọ́ sínú ìdẹwò." 41 Ó fi wọ́n sílẹ̀ níwọ̀n ìsọ-òkò kan, ó kúnlẹ̀ ó ń gbàdúrà. 42 , "Baba, ìwọ fẹ́, mu ago yìí kúrò lọ́dọ́ mi: ṣùgbọ́n ìfẹ́ ti èmi kọ́, ṣe tìrẹ ni à ṣe." 43 Angẹli kan yọ i láti ̀run , ó ń gbà á ìyànjú. 44 ó ti nínú gbígbóná ara ó ń gbàdúrà i kíkankíkan; òógùn rẹ̀ dàbí ìró ̀jẹ̀ ńlá, ó ń kán sílẹ̀.

45 Nígbà ó dìde kúrò ibi àdúrà, ó tọ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , ó wọn, wọ́n ń sùn nítorí ìbànújẹ́ ti mu ó rẹ̀ wọ́n. 46 Ó fún wọn , "ni ̀ yin ń sùn ? dìde, máa gbàdúrà, ̀yin ṣe bọ́ sínú ìdẹwò."

Wọ́n Jesu

47 ó ti ń sọ lọ́wọ́, kíyèsi i, ̀pọ̀ ènìyàn, àti ẹni a ń Judasi, ̀kan nínú àwọn méjìlá, ó ṣáájú wọn, ó súnmọ́ Jesu láti fi ẹnu ó ẹnu. 48 Jesu fún un , "Judasi, ìwọ yóò ha fi ìfẹnukonu fi Ọmọ Ènìyàn hàn?"

49 Nígbà àwọn ó lọ́dọ̀ rẹ̀ ń wo nǹkan yóò ti jásí, wọ́n bi í , "Olúwa àwa fi idà wọn?" 50 ̀kan nínú wọn fi idà ṣá ọmọ ̀dọ̀ olórí àlùfáà, ó etí ̀tún rẹ̀ sọnù.

51 Ṣùgbọ́n Jesu dáhùn ó , "Ko gbọdọ̀ ṣe èyí mọ." Ó fi ọwọ́ tọ́ etí, ó ó sàn.

52 Jesu fún àwọn olórí àlùfáà, àti àwọn olórí ̀ṣọ́ tẹmpili, àti àwọn alàgbà, wọ́n jáde tọ̀ ́ , "̀yin ha jáde pẹ̀idà àti ̀kọ̀ ẹni tọ ọlọ́ṣà ? 53 Nígbà èmi pẹ̀yín lójoojúmọ́ tẹmpili, ̀yin na ọwọ́ mi, ṣùgbọ́n àkókò tiyín ni èyí, àti agbára òkùnkùn n jẹ ọba."

Peteru sẹ́ Jesu

54 Wọ́n gbá a , wọ́n á lọ, wọ́n un ilé olórí àlùfáà. Ṣùgbọ́n Peteru tọ̀ ́ lẹ́yìn òkèrè. 55 Nígbà wọ́n ti dáná láàrín àgbàlá, wọ́n jókòó pọ̀, Peteru jókòó láàrín wọn. 56 Ọmọbìnrin kan i ó ti jókòó níbi ìmọ́lẹ̀ iná náà, ó tẹjúmọ́ ọn, ó , "Eléyìí náà pẹ̀rẹ̀."

57 Ṣùgbọ́n, ó , "Obìnrin yìí, èmi mọ̀ ́n."

58 pẹ́ lẹ́yìn náà ẹlòmíràn i, ó , "Ìwọ pẹ̀nínú wọn."

Ṣùgbọ́n Peteru , "Ọkùnrin yìí, èmi kọ́."

59 Ó i wákàtí kan síbẹ̀ ẹlòmíràn tẹnumọ́ ọn, , "Nítòótọ́ eléyìí náà pẹ̀rẹ̀: nítorí ará Galili í ṣe."

60 Ṣùgbọ́n Peteru , "Ọkùnrin yìí, èmi mọ ohun ìwọ ń !" Lójúkan náà, ó ń lẹ́nu, àkùkọ kọ! 61 Olúwa yípadà, ó wo Peteru. Peteru rántí ̀rọ̀ Olúwa, ó ti fún un , "àkùkọ kọ, ìwọ ó sẹ́ mi lẹ́̀mẹ́ta." 62 Peteru bọ́ òde, ó sọkún kíkorò.

Àwọn ̀ṣọ́ n gan Jesu

63 Ó ṣe, àwọn ọkùnrin wọ́n Jesu, fi í ṣe ẹlẹ́, wọ́n ú. 64 Nígbà wọ́n í ojú, wọ́n ú níwájú, wọ́n ń bi í , "Sọtẹ́lẹ̀! Ta ni ó ́?" 65 Wọ́n sọ ̀pọ̀ ohun búburú mìíràn i, láti fi ṣe ẹlẹ́.

Jesu níwájú Pilatu àti Herodu

66 Nígbà ilẹ̀ mọ́, ìjọ àwọn alàgbà àwọn ènìyàn péjọpọ̀, àti àwọn olórí àlùfáà, àti àwọn akọ̀, wọ́n á lọ àjọ wọn, wọ́n ń , 67 "ìwọ jẹ́ Kristi náà? Sọ fún wa!"

Ó fún wọn , "mo fún yín, ̀yin yóò gbàgbọ́, 68 mo bi yín léèrè pẹ̀, ̀yin yóò mi lóhùn. 69 Ṣùgbọ́n láti ìsinsin yìí lọ ni Ọmọ Ènìyàn yóò jókòó lọ́wọ́ ̀tún agbára Ọlọ́run."

70 Gbogbo wọn , "Ìwọ ha ṣe Ọmọ Ọlọ́run ?"

Ó fún wọn , "̀yin , èmi ni."

71 Wọ́n , "̀wo ni àwa tún ń fẹ́ àwa tìkára wa à ti gbọ́ lẹ́nu rẹ̀!"

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-