Pular para o conteúdo
Publicidade

Miquéias 7

Ìrora Israẹli

1 Ègbé ni fún mi!

Nítorí èmi dàbí ẹni ń èso ̀̀rùn jọ,

ìpèsè ọgbà àjàrà;

ṣí odidi àjàrà kankan láti jẹ,

ṣí àkọ́so ̀pọ̀tọ́ nítorí ebi ń pa .

2 Àwọn olódodo ti kúrò ilẹ̀ náà,

ṣí ẹnìkan ó ṣẹ́ó jọ olóòtítọ́;

gbogbo wọn ń purọ́ dídúró nítorí ìtàjẹ̀ sílẹ̀,

olúkúlùkù wọ́n ń fi àwọ̀n de arákùnrin rẹ̀.

3 Ọwọ́ wọn méjèèjì ti múra tán láti ṣe búburú;

àwọn alákòóso ń béèrè fún ̀bùn,

àwọn onídàájọ́ ń gba owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀

alágbára ń pàṣẹ ohun wọ́n fẹ́,

gbogbo wọn jùmọ̀ ń dìtẹ̀.

4 Ẹni ó sàn jùlọ nínú wọn dàbí ̀gún,

ẹni ó jẹ́ olódodo jùlọ burú ju ̀gún ọgbà lọ.

Ọjọ́ àwọn olùṣọ́ rẹ̀ ti ,

àti ọjọ́ Ọlọ́run bẹ̀ ́ .

Nísinsin yìí àkókò ìdààmú wọn.

5 ṣe gba ̀rẹ́ kan gbọ́;

ṣe gbẹ́kẹ̀amọ̀kankan.

Pa ìlẹ̀kùn ẹnu rẹ fún ẹni

ó sùn oókan àyà rẹ.

6 7.6: Mt 10.21,35,36; Mk 13.12; Lk 12.53. Nítorí ọmọkùnrin bọ̀wọ̀ fún baba rẹ̀,

ọmọbìnrin dìde ìyá rẹ̀,

aya ọmọ ìyá ọkọ rẹ̀,

̀olúkúlùkù ni àwọn ará ilé rẹ̀.

7 Ṣùgbọ́n tèmi, èmi ìwòye ìrètí Olúwa,

èmi dúró de Ọlọ́run olùgbàlà mi;

Ọlọ́run mi yóò tẹ́mi.

Israẹli yóò dìde

8 ṣe yọ̀ , ìwọ ̀mi.

ṣubú, èmi yóò dìde.

Nígbà mo jókòó sínú òkùnkùn

Olúwa yóò jẹ́ ìmọ́lẹ̀ fún mi.

9 Nítorí èmi ti dẹ́ṣẹ̀ i,

èmi yóò faradà ìbínú Olúwa,

títí òun yóò ṣe gba ẹjọ́ mi ,

yóò ṣe ìdájọ́ mi.

Òun yóò mi sínú ìmọ́lẹ̀;

èmi yóò òdodo rẹ̀.

10 Nígbà náà ni ̀mi yóò i

ìtìjú yóò bo ẹni ó fún mi ,

"Níbo ni Olúwa Ọlọ́run rẹ ?"

Ojú mi yóò ìṣubú rẹ̀;

nísinsin yìí ni yóò di ìtẹ̀mọ́lẹ̀

ẹrẹ̀ òpópó.

11 Ọjọ́ a ó mọ odi rẹ yóò ,

ọjọ́ náà ni àṣẹ yóò jìnnà réré.

12 ọjọ́ náà àwọn ènìyàn yóò sọ́dọ̀ rẹ

láti Asiria àti ìlú ńlá Ejibiti

àní láti Ejibiti Eufurate

láti Òkun Òkun

àti láti òkè ńlá òkè ńlá.

13 Ilẹ̀ náà yóò di ahoro fún àwọn olùgbé inú rẹ̀,

nítorí èso ìwà wọn.

Àdúrà àti ìyìn

14 Fi ̀rẹ bọ́ àwọn ènìyàn, agbo ẹran ìní rẹ,

èyí ó ń dágbé nínú igbó

àárín Karmeli.

Jẹ́ wọn jẹun Baṣani àti Gileadi

ọjọ́ ìgbàanì.

15 "i ọjọ́ ó jáde kúrò Ejibiti ,

ni èmi yóò fi ohun ìyanu hàn án."

16 Orílẹ̀-èdè yóò i, ojú yóò wọ́n,

nínú gbogbo agbára wọn.

Wọn yóò fi ọwọ́ ẹnu wọn,

etí wọn yóò di.

17 Wọn yóò erùpẹ̀ ejò,

wọn yóò jáde kúrò nínú ihò wọn ekòló.

Wọn yóò bẹ̀Olúwa Ọlọ́run wa,

wọn yóò bẹ̀nítorí rẹ̀.

18 Ta ni Ọlọ́run rẹ̀,

ẹni ó dárí ̀ṣẹ̀ ,

ó fojú fo ìrékọjá èyí tókù ìní rẹ̀?

í dúró nínú ìbínú rẹ̀ láéláé

nítorí òun inú dídùn àánú.

19 Òun yóò tún padà yọ́wa;

òun yóò tẹ àwọn ̀ṣẹ̀ wa mọ́lẹ̀,

yóò fa gbogbo àìṣedéédéé wa sínú ibú Òkun.

20 7.20: Lk 1.55. Ìwọ yóò fi òtítọ́ hàn Jakọbu

ìwọ yóò fi àánú hàn Abrahamu,

ìwọ ṣe búra fún àwọn baba wa

láti ọjọ́ ìgbàanì.

Veja também