Publicidade

Zacarias 8

Ọlọ́run ṣe ìpinnu láti bùkún Jerusalẹmu

1 ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun si tún tọ́ .

2 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , "Owú ńlá ńlá ni mo jẹ fún Sioni, pẹ̀ìbínú ńlá ńlá ni mo fi jowú fún un."

3 Báyìí ni Olúwa , "Mo yípadà Sioni èmi ó gbé àárín Jerusalẹmu. Nígbà náà ni a ó Jerusalẹmu ni ìlú ńlá òtítọ́; àti òkè ńlá Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ni a ó òkè ńlá mímọ́."

4 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , "Arúgbó ọkùnrin, àti arúgbó obìnrin, yóò gbé ìgboro Jerusalẹmu, àti olúkúlùkù pẹ̀̀ni ọwọ́ rẹ̀ fún ogbó. 5 Ìgboro ìlú yóò kún fún ọmọdékùnrin, àti ọmọdébìnrin, ń ṣiré ìta wọn."

6 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , "ó ṣe ìyanu ojú ìyókù àwọn ènìyàn yìí ni ọjọ́ wọ̀nyí, ǹjẹ́ ó ha jẹ́ ìyanu ni ojú mi ?" ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

7 Báyìí Olúwa àwọn ọmọ-ogun , "Kíyèsi i, èmi ó gba àwọn ènìyàn mi kúrò ni ilẹ̀ ìlà-oòrùn, àti kúrò ni ilẹ̀ ìwọ̀-oòrùn. 8 Èmi ó wọn padà , wọn ó máa gbé àárín Jerusalẹmu. Wọn ó jẹ́ ènìyàn mi, èmi ó jẹ́ Ọlọ́run wọn, òtítọ́, àti òdodo."

9 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , "Jẹ́ ọwọ́ yín le ̀yin ti ń gbọ́ ̀rọ̀ wọ̀nyí ọjọ́ wọ̀nyí ni ẹnu àwọn wòlíì ó ni ọjọ́ a fi ìpìlẹ̀ ilé Olúwa àwọn ọmọ-ogun lélẹ̀, jẹ́ ki ọwọ́ rẹ̀ le a kọ́ tẹmpili. 10 Nítorí , ṣáájú ọjọ́ wọ̀nyí, owó ̀ènìyàn nǹkan, bẹ́̀ ni ̀ẹran pẹ̀, bẹ́̀ ni àlàáfíà fún ẹni ń jáde lọ, tàbí ẹni ti ń wọlé bọ, nítorí ìpọ́njú náà: nítorí mo dojú gbogbo ènìyàn, olúkúlùkù kọ aládùúgbò rẹ̀. 11 Ṣùgbọ́n ìsinsin yìí èmi yóò ṣè ìyókù àwọn ènìyàn yìí gẹ́gẹ́ ìgbà àtijọ́," ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

12 "Nítorí irúgbìn yóò gbilẹ̀, àjàrà yóò ṣo èso rẹ̀, ilẹ̀ yóò hu ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan rẹ̀ jáde, àwọn ̀run yóò mu ìrì wọn ; èmi ó mu èyí jẹ ogún ìní àwọn ìyókù ènìyàn yìí ni gbogbo nǹkan wọ̀nyí. 13 Yóò ṣe, gẹ́gẹ́ ̀yin jẹ́ ègún láàrín àwọn kèfèrí, ̀yin ilé Juda, àti ilé Israẹli, bẹ́̀ ni èmi ó gbà yín sílẹ̀; ̀yin o jẹ́ ìbùkún, bẹ̀, ṣùgbọ́n jẹ́ ki ọwọ́ yín le."

14 Nítorí báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun : "Gẹ́gẹ́ mo ti láti ṣe yín níbi nígbà àwọn baba yín mi bínú," ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , èmi ronúpìwàdà. 15 "Bẹ́̀ ni èmi ti ro ọjọ́ wọ̀nyí láti ṣe rere fún Jerusalẹmu, àti fún ilé Juda: bẹ̀. 16 8.16: Ef 4.25.Wọ̀nyí ni nǹkan ̀yin ó ṣe: ki olúkúlùkù yín ó máa ba ọmọnìkejì rẹ̀ sọ òtítọ́; ṣe ìdájọ́ tòótọ́ àti àlàáfíà àwọn ibodè yín. 17 ṣe jẹ́ ẹnìkan ro ibi ni ọkàn rẹ̀ ẹnìkejì rẹ̀; fẹ́ ìbúra èké; nítorí gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni mo kórìíra," ni Olúwa .

18 ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun tọ mi .

19 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun : "Àwẹ̀ oṣù kẹrin, karùn-ún, keje, àti ̀kẹwàá, yóò jẹ́ ayọ̀ àti dídùn inú, àti àpéjọ àríyá fún ilé Juda; nítorí náà, fẹ́ òtítọ́ àti àlàáfíà."

20 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , "Àwọn ènìyàn yóò à tún wa, àti ẹni yóò gbe ìlú ńlá púpọ̀. 21 Àwọn ẹni ń gbé ìlú ńlá kan yóò lọ òmíràn, , jẹ́ a yára lọ gbàdúrà a ojúrere Olúwa, àti láti Olúwa àwọn ọmọ-ogun. Èmi pẹ̀yóò lọ.22 Nítòótọ́, ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn àti àwọn alágbára orílẹ̀-èdè yóò láti Olúwa àwọn ọmọ-ogun Jerusalẹmu; àti láti gbàdúrà, àti láti ojúrere Olúwa."

23 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , "àwọn ọjọ́ wọ̀nyí ni ọkùnrin mẹ́wàá láti inú gbogbo èdè àti orílẹ̀-èdè yóò dìímú, àní yóò di etí aṣọ ẹni i ṣe Júù , , Àwa yóò ba lọ, nítorí àwa gbọ́ , Ọlọ́run pẹ̀rẹ.’ "

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-