Publicidade

amor de Deus

Por Bíblia Online

O amor de Deus é a maior realidade do universo. Ele nos amou com amor eterno, incondicional e sacrificial — e nada no mundo pode nos separar desse amor.

Amor eterno

Deus amou o mundo de tal maneira que deu o seu Filho. Seu amor é de eternidade a eternidade — nunca falha.

"Nítorí Ọlọ́run fẹ́ aráyé bẹ́̀ gẹ́́, ó fi ọmọ rẹ̀ kan ṣoṣo fún ni, ẹnikẹ́ni ó gbà á gbọ́, á ṣègbé, ṣùgbọ́n ó ìyè àìnípẹ̀kun.

Ṣùgbọ́n Ọlọ́run fi ìfẹ́ òun pàápàá wa hàn nínú èyí , nígbà àwa jẹ́ ẹlẹ́ṣẹ̀, Kristi fún wa.

Nítorí ó mi lójú gbangba , í ṣe ikú tàbí ìyè, í ṣe àwọn angẹli tàbí ̀èṣù, í ṣe ohun ìgbà ìsinsin yìí tàbí ohun ó ń bọ̀, tàbí àwọn agbára, tàbí òkè, tàbí ̀gbun, tàbí ohunkóhun nínú ìṣẹ̀ni yóò le kúrò nínú ìfẹ́ Ọlọ́run ó ń bẹ nínú Kristi Jesu, Olúwa wa.

Olúwa ti fi ara rẹ̀ hàn ìgbà kan , ó :

"Èmi ti nífẹ̀́ yín pẹ̀ìfẹ́ àìlópin;

mo ti fi ìfẹ́ ńlá yín,

fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí ó ṣeun;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

Olúwa ni aláàánú àti olóore,

ó lọ́ra láti bínú, ó pọ̀ ìfẹ́.

Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, jẹ́ aláàánú àti Ọlọ́run olójúrere,

Ó lọ́ra láti bínú, Ó pọ̀ ìfẹ́ àti òtítọ́.

Nítorí ìfẹ́ rẹ dára ju ayé lọ,

ètè mi yóò fògo fún .

Natureza do amor divino

Deus é amor. O amor é paciente, benigno. O amor do Pai nos adota como filhos e nos transforma à sua imagem.

Ìfẹ́ Ọlọ́run àti ti àwa

Olùfẹ́, jẹ́ a fẹ́ràn ara wa, nítorí ìfẹ́ ti ̀dọ̀ Ọlọ́run ; àti gbogbo ẹni ó ìfẹ́, a i nípa ti Ọlọ́run, ó mọ Ọlọ́run. Ẹni ìfẹ́ mọ Ọlọ́run: nítorí ìfẹ́ ni Ọlọ́run.

Nípa èyí ni a gbé fi ìfẹ́ Ọlọ́run hàn nínú wa, nítorí Ọlọ́run rán ọmọ bíbí rẹ̀ nìkan ṣoṣo ayé, àwa nípasẹ̀ rẹ̀. Nínú èyí ni ìfẹ́ , í ṣe àwa fẹ́ Ọlọ́run, ṣùgbọ́n òun fẹ́ , ó rán Ọmọ rẹ̀ láti jẹ́ ètùtù fún ̀ṣẹ̀ wa. Olùfẹ́, Ọlọ́run fẹ́ wa báyìí, ó yẹ a fẹ́ràn ara wa pẹ̀.

Báyìí ni àwa mọ̀, a gba ìfẹ́ Ọlọ́run wa gbọ́.

Ìfẹ́ ni Ọlọ́run; ẹni ó ń gbé inú ìfẹ́, ó ń gbé inú Ọlọ́run, àti Ọlọ́run nínú rẹ̀.

Àwa fẹ́ràn rẹ̀ nítorí òun ni ó kọ́ fẹ́ràn wa.

wo irú ìfẹ́ Baba fi fẹ́ wa, a fi ń ọmọ Ọlọ́run; bẹ́̀ ni a à jẹ́. Nítorí èyí ni ayé ṣe mọ̀ , nítorí mọ̀ ́n.

̀yin olùfẹ́ ̀wọ́n, í ṣe òfin tuntun ni mo ń kọ̀rẹ̀ yín ṣùgbọ́n òfin àtijọ́, èyí ̀yin gbọ́ àtètèkọ́ṣe. Òfin àtijọ́ ni ̀rọ̀ náà ̀yin gbọ́. Pẹ̀lúpẹ̀, òfin tuntun ni mo ń kọ̀rẹ̀ yín; èyí í ṣe òtítọ́ nínú rẹ̀ àti nínú yin, nítorí òkùnkùn ń kọjá lọ, ìmọ́lẹ̀ òtítọ́ ń tàn.

Nítorí èyí ni ìfẹ́ Ọlọ́run, àwa pa òfin rẹ̀ mọ́: òfin rẹ̀ nira,

Ìfẹ́ a máa sùúrù, ìfẹ́ a máa ṣeun, ìfẹ́ í ṣe ìlara, ìfẹ́ í fẹ̀, ìfẹ́ í sọ̀rọ̀ ìgbéraga.

Expressões do amor de Deus

O Senhor nos ama com alegria e canta sobre nós. Queni a mim vem, amará; e quem me ama, o Pai o amará.

Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀rẹ,

Ó agbára láti gbà .

Yóò yọ̀ ni orí rẹ fún ayọ̀;

Yóò tún ṣe nínú ìfẹ́ rẹ̀,

Yóò fi orin yọ̀ orí rẹ."

Mo fẹ́ràn àwọn ó fẹ́ràn mi,

àwọn ó mi mi.

Nítorí o ṣe iyebíye àti ̀wọ́n níwájú mi,

àti nítorí mo fẹ́ràn rẹ,

Èmi yóò fi ènìyàn rọ́fún ,

àti ènìyàn dípò ̀rẹ.

Láàrín tẹmpili rẹ, Ọlọ́run,

àwa ti ń sọ ti ìṣeun ìfẹ́ rẹ.

ìṣeun ìfẹ́ ̀ rẹ àwọn ó mọ̀ ́n

àti ìgbàlà rẹ àwọn ó ìdúró ṣinṣin ọkàn!

A ti kàn mọ́ àgbélébùú pẹ̀Kristi, èmí láààyè mọ́, ṣùgbọ́n Kristi ń gbé inú mi wíwà mo láààyè nínú ara, mo láààyè nínú ìgbàgbọ́ Ọmọ Ọlọ́run, ẹni o fẹ́ mi, ó fi òun tìkára rẹ̀ fún mi.

Ṣùgbọ́n Ọlọ́run, ẹni í ṣe ọlọ́rọ̀ ni àánú, nítorí ìfẹ́ ńlá rẹ̀ ó fi fẹ́ wa, nígbà àwa tilẹ̀ ti nítorí ìrékọjá wa, ó sọ di ààyè pẹ̀Kristi, oore-ọ̀fẹ́ ni a ti fi gbà yín .

Oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa, àti ìfẹ́ Ọlọ́run, àti ìdàpọ̀ ti Èmí Mímọ́, ó pẹ̀gbogbo yín.

Olúwa máa tọ́ ọkàn yín ṣọ́ìfẹ́ Ọlọ́run àti sínú sùúrù Kristi.

Seja o primeiro
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-