Publicidade

Salmos 48

Orin. Saamu ti àwọn ọmọ Kora.

1 Ẹni ńlá Olúwa, ó yẹ láti máa yìn

ìlú Ọlọ́run wa, lórí òkè mímọ́ rẹ̀.

2 Ó dára nínú ipò ìtẹ́ rẹ̀,

ayọ̀ gbogbo ayé,

òkè Sioni, ìhà àríwá

ìlú ọba ńlá.

3 Ọlọ́run nínú ààbò ààfin rẹ̀;

ó fi ara rẹ̀ hàn láti jẹ́ odi alágbára.

4 Nígbà àwọn ọba kógun jọ pọ̀,

wọ́n jùmọ̀ ń kọjá lọ.

5 Wọn i, bẹ́̀ ni ẹnu wọ́n,

a yọ wọ́n lẹ́nu, wọ́n yára lọ.

6 ̀wọ́n níbẹ̀,

ìrora gẹ́gẹ́ obìnrin ó nínú ìrọbí.

7 Ìwọ wọ́n jẹ́ gẹ́gẹ́ ọkọ̀ orí omi Tarṣiṣi,

wọ́n fọ́nká láti ọwọ́ ìjì ìlà-oòrùn.

8 Gẹ́gẹ́ a ṣe gbọ́,

bẹ́̀ ni àwa ,

inú Olúwa àwọn ọmọ-ogun

ìlú Ọlọ́run wa,

Ọlọ́run jẹ́ ó abẹ́ ààbò títí láéláé. Sela.

9 Láàrín tẹmpili rẹ, Ọlọ́run,

àwa ti ń sọ ti ìṣeun ìfẹ́ rẹ.

10 Gẹ́gẹ́ orúkọ rẹ Ọlọ́run,

ìyìn rẹ̀ òpin ayé,

ọwọ́ ̀tún rẹ kún fún òdodo.

11 Jẹ́ òkè Sioni ó yọ̀

inú àwọn ọmọbìnrin Juda ó dùn

nítorí ìdájọ́ rẹ.

12 Rìn Sioni kiri lọ yíká rẹ̀,

ka ilé ìṣọ́ rẹ̀.

13 Kíyèsi odi rẹ̀,

kíyèsi àwọn ààfin rẹ̀

̀yin máa fún ìran ń bọ̀.

14 Nítorí Ọlọ́run yìí Ọlọ́run títí ayé,

Òun ni yóò ṣe amọ̀wa títí òpin ayé.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-