Publicidade

Isaías 43

Olùgbàlà Israẹli kan ṣoṣo

1 Ṣùgbọ́n ìsinsin yìí, ohun Olúwa nìyìí,

ẹni ó , ìwọ Jakọbu,

ẹni ó mọ ́, ìwọ Israẹli:

"bẹ̀, nítorí Èmi ti nídè;

Èmi ti ́ orúkọ; tèmi ni ìwọ ṣe.

2 Nígbà ìwọ ń la omi kọjá,

Èmi yóò pẹ̀rẹ;

àti nígbà ìwọ ń la odò kọjá

wọn yóò ́ mọ́lẹ̀.

Nígbà ìwọ la iná kọjá,

;

ahọ́n iná lára.

3 Nítorí Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ,

Ẹni Mímọ́ Israẹli Olùgbàlà rẹ;

Èmi fi Ejibiti ṣe ìràpadà rẹ,

Kuṣi àti Seba dípò rẹ.

4 Nítorí o ṣe iyebíye àti ̀wọ́n níwájú mi,

àti nítorí mo fẹ́ràn rẹ,

Èmi yóò fi ènìyàn rọ́fún ,

àti ènìyàn dípò ̀rẹ.

5 bẹ̀nítorí èmi pẹ̀rẹ;

Èmi yóò àwọn ọmọ rẹ láti ìlà-oòrùn

èmi ó jọ láti ìwọ̀-oòrùn.

6 Èmi yóò sọ fún àríwá , Fi wọ́n sílẹ̀!’

Àti fún gúúsù, ṣe wọn dúró.

àwọn ọmọkùnrin mi láti ̀jíjìn

àti àwọn ̀dọ́mọbìnrin mi láti ìpẹ̀kun ilẹ̀ ayé

7 ẹnikẹ́ni a ń pe orúkọ mi mọ́,

mo fún ògo mi,

mo mọ̀ àti mo ṣe."

8 Sin àwọn ó ojú ṣùgbọ́n wọ́n fọ́jáde,

wọ́n etí ṣùgbọ́n wọn dití.

9 Gbogbo orílẹ̀-èdè ra wọn jọ

àwọn ènìyàn ra wọn papọ̀.

Ta ni nínú wọn sọ àsọtẹ́lẹ̀ yìí

ó kéde fún wa àwọn nǹkan ti tẹ́lẹ̀?

Jẹ́ wọ́n àwọn ẹlẹ́rìí wọn wọlé

láti fihàn wọ́n tọ̀

bẹ́̀ àwọn mìíràn yóò gbọ́,

wọn yóò sọ , "Òtítọ́ ni."

10 "̀yin ni ẹlẹ́rìí mi," ni Olúwa ,

"Àti ìránṣẹ́ mi èmi ti yàn,

bẹ́̀ ̀yin yóò fi mọ̀ àti ̀yin ó fi gbà gbọ́

yóò e yín èmi ni ẹni náà.

Ṣáájú mi ọlọ́run a ,

tàbí a ó wa òmíràn lẹ́yìn mi.

11 Èmi, àní Èmi, Èmi ni Olúwa,

yàtọ̀ èmi, olùgbàlà mìíràn.

12 Èmi ti fihàn, mo gbàlà mo ti kéde

Èmi, í í ṣe àwọn àjèjì òrìṣà láàrín yín.

̀yin ni ẹlẹ́rìí mi," ni Olúwa , "Èmi ni Ọlọ́run.

13 Bẹ́̀ ni, àti láti ayérayé Èmi ni ẹni náà.

ẹnikẹ́ni ó gbà kúrò lọ́wọ́ mi.

Nígbà mo ṣe nǹkan, ta ni ó i padà?"

Àánú Ọlọ́run àti àìṣòdodo Israẹli

14 Èyí ni ohun Olúwa ,

olùràpadà rẹ, Ẹni Mímọ́ ti Israẹli:

"Nítorí rẹ Èmi yóò ránṣẹ́ Babeli

láti wọn sọ̀kalẹ̀ gẹ́gẹ́ ìsáǹsá, gbogbo ará Babeli,

nínú ọkọ̀ ojú omi nínú èyí wọ́n fi ń ṣe ìgbéraga.

15 Èmi ni Olúwa, Ẹni Mímọ́ rẹ,

Ẹlẹ́dàá Israẹli, ọba rẹ."

16 Èyí ni ohun Olúwa ,

Ẹni náà ó la ̀nínú Òkun,

ipa ̀láàrín alagbalúgbú omi,

17 ẹni ó wọ́ àwọn kẹ̀kẹ́ àti ẹṣin jáde,

àwọn jagunjagun àti ohun ìjà papọ̀,

wọ́n sùn síbẹ̀, láìní dìde mọ́,

wọ́n pirá òwú-fìtílà:

18 "Gbàgbé àwọn ohun àtẹ̀yìnwá;

ṣe gbé nínú ohun àtijọ́.

19 ó, Èmi ń ṣe ohun tuntun!

Nísinsin yìí, ó ti yọ sókè; àbí o i ?

Èmi ń ṣe ̀kan nínú aṣálẹ̀

àti odò nínú ilẹ̀ ṣíṣá.

20 Àwọn ẹhànnà ẹranko bọ̀wọ̀ fún mi,

àwọn ajáko àti àwọn òwìwí,

nítorí mo pèsè omi nínú aṣálẹ̀

àti odò nínú ilẹ̀ sísá,

láti fi ohun mímu fún àwọn ènìyàn mi, àyànfẹ́ mi,

21 àwọn ènìyàn mo fún ara mi

wọn ó kéde ìyìn mi.

22 "Síbẹ̀síbẹ̀ ìwọ ì , ìwọ Jakọbu,

àárẹ̀ ì nítorí mi ìwọ Israẹli.

23 Ìwọ ì àgùntàn fún mi fún ẹbọ sísun,

tàbí o bọ̀wọ̀ fún mi pẹ̀ẹbọ rẹ.

Èmi ì wàhálà rẹ pẹ̀ọrẹ ìyẹ̀fun

tàbí n dààmú rẹ pẹ̀ìbéèrè fún tùràrí.

24 Ìwọ ì ra kalamusi olóòórùn dídùn fún mi,

tàbí o da ̀ẹbọ rẹ .

Ṣùgbọ́n ti wàhálà mi pẹ̀̀ṣẹ̀ yín

ti dààmú mi pẹ̀àìṣedéédéé yín.

25 "Èmi, àní Èmi, Èmi ni ẹni ó wẹ

àwọn àìṣedéédéé rẹ , nítorí èmi fún ara mi,

n rántí àwọn ̀ṣẹ̀ rẹ mọ́.

26 Bojú wo ̀yìn rẹ fún mi,

jẹ́ a jọ ṣe àríyànjiyàn ̀rọ̀ náà papọ̀;

ro ẹjọ́ láti fihàn o lẹ́sẹ̀ lọ́rùn.

27 Baba yín àkọ́kọ́ dẹ́ṣẹ̀;

àwọn agbẹnusọ yín ṣọ̀tẹ̀ mi.

28 Nítorí náà, èmi ti sọ àwọn olórí ibi mímọ́ náà di àìmọ́,

bẹ́̀ ni èmi ti fi Jakọbu fún ègún

àti Israẹli fún ̀gàn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-