Publicidade

Salmos 36

Fún adarí orin. Ti Dafidi ìránṣẹ́ Olúwa.

1 36.1: Ro 3.18. Ìré-òfin-kọjá ènìyàn búburú

jẹ́ n mọ̀ nínú ọkàn mi ,

ìbẹ̀Ọlọ́run

níwájú wọn.

2 Nítorí wọ́n pọ́n ara wọn ojú ara wọn

títí a fi le ̀ṣẹ̀ wọn láti kórìíra.

3 ̀rọ̀ ẹnu wọn ni ̀ṣẹ̀ òhun ̀tàn;

wọ́n ti fi ọgbọ́n àti ṣíṣe rere sílẹ̀.

4 Wọ́n gbìmọ̀ ìwà ìkà nígbà wọ́n lórí ibùsùn wọn:

wọ́n gba ̀dára

wọn kọ ̀ibi sílẹ̀.

5 Ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ rẹ, ìwọ Olúwa, ó ga ̀run,

òtítọ́ ̀ rẹ ga àwọsánmọ̀.

6 Òdodo rẹ dàbí àwọn òkè Ọlọ́run,

àwọn ìdájọ́ rẹ dàbí ibú ńlá;

ìwọ gba ẹranko àti ènìyàn , Olúwa.

7 Báwo ni ìṣeun ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ rẹ ti ! Ọlọ́run!

gbogbo ọmọ ènìyàn le abẹ́ òjìji ìyẹ́ rẹ.

8 Àsè ilé rẹ yóò tẹ́ wọn lọ́rùn gidigidi;

ìwọ yóò wọn mu nínú odò inú dídùn rẹ.

9 Nítorí pẹ̀rẹ ni orísun ìyè :

nínú ìmọ́lẹ̀ rẹ ni àwa yóò ìmọ́lẹ̀.

10 ìṣeun ìfẹ́ ̀ rẹ àwọn ó mọ̀ ́n

àti ìgbàlà rẹ àwọn ó ìdúró ṣinṣin ọkàn!

11 ṣe jẹ́ ẹsẹ̀ agbéraga ó orí mi,

o jẹ́ ọwọ́ àwọn ènìyàn búburú mi ipò.

12 Níbẹ̀ ni àwọn oníṣẹ́ ̀ṣẹ̀ gbé ṣubú :

a rẹ̀ wọ́n sílẹ̀, wọn yóò le è dìde!

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-