Publicidade

Salmos 103

Ti Dafidi.

1 Yin Olúwa, ìwọ ọkàn mi; àti gbogbo ohun ó nínú mi, yín orúkọ rẹ̀ mímọ́.

2 Yin Olúwa, ìwọ ọkàn mi, o ṣe gbàgbé gbogbo oore rẹ̀,

3 ẹni ó dárí gbogbo ̀ṣẹ̀ rẹ̀ ́

ó wo gbogbo ààrùn rẹ̀ sàn,

4 ẹni ó ra ̀rẹ padà kúrò nínú kòtò ikú

ẹni ó fi ìṣeun ìfẹ́ àti ìyọ́adé,

5 ẹni ó fi ohun dídára tẹ́ lọ́rùn

ìgbà èwe rẹ̀ di ̀tún ti ẹyẹ idì.

6 Olúwa ń ṣe òdodo àti ìdájọ́ fún

gbogbo àwọn a ni lára.

7 Ó fi ̀rẹ̀ hàn fún Mose, iṣẹ́ rẹ̀ fun àwọn ọmọ Israẹli;

8 Olúwa ni aláàánú àti olóore,

ó lọ́ra láti bínú, ó pọ̀ ìfẹ́.

9 Òun í ni ìgbà gbogbo

bẹ́̀ ni í pa ìbínú rẹ mọ́ láéláé,

10 Òun í ṣe wa gẹ́gẹ́ ̀ṣẹ̀ wa

bẹ́̀ ni í san án fún wa gẹ́gẹ́

àìṣedéédéé wa.

11 Nítorí ̀run ṣe ga sílẹ̀,

bẹ́̀ ni ìfẹ́ rẹ̀ tóbi àwọn ó bẹ̀rẹ̀.

12 ìlà-oòrùn ti jìnnà ìwọ̀-oòrùn

bẹ́̀ ni ó ṣe ìrékọjá jìnnà wa.

13 baba ti ń ṣe ìyọ́àwọn ọmọ rẹ̀,

bẹ́̀ ni Olúwa ń ṣe ìyọ́àwọn ó bẹ̀rẹ̀,

14 nítorí ó mọ dídá wa,

ó rántí erùpẹ̀ ni .

15 ó ṣe ti ènìyàn ni, ọjọ́ rẹ̀ dàbí koríko,

ó gbilẹ̀ ìtànná ewéko igbó,

16 afẹ́fẹ́ fẹ́ kọjá lọ lórí rẹ̀,

rántí ibùjókòó rẹ̀ mọ́.

17 Ṣùgbọ́n láti ayérayé ni ìfẹ́

Olúwa ti pẹ̀àwọn ó bẹ̀rẹ̀,

àti òdodo rẹ̀ láti ọmọdọ́mọ,

18 àwọn ó pa májẹ̀rẹ̀ mọ́

àti àwọn ó rántí òfin rẹ̀ láti ṣe wọ́n.

19 Olúwa ti pèsè ìtẹ́ rẹ̀ nínú ̀run,

ìjọba rẹ̀ ó borí ohun gbogbo.

20 Yin Olúwa, ̀yin angẹli rẹ̀,

ó ipá,

ó pa òfin ̀rọ̀ rẹ̀ mọ́, ó ń se ìfẹ́ rẹ̀.

21 Yin Olúwa, ̀yin ogun ̀run rẹ̀ gbogbo,

̀yin ìránṣẹ́ rẹ̀ ń ṣe ìfẹ́ rẹ̀.

22 Yin Olúwa, gbogbo iṣẹ́ rẹ̀

ibi gbogbo ìjọba rẹ̀.

Yin Olúwa, ìwọ ọkàn mi.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-