Publicidade

Salmos 136

1 fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí ó ṣeun;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

2 fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run àwọn ọlọ́run:

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

3 fi ọpẹ́ fún Olúwa àwọn olúwa,

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

4 Fún Òun nìkan ń ṣiṣẹ́ ìyanu ńlá;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

5 Fún ẹni ó fi ọgbọ́n ̀run;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

6 Fún ẹni ó tẹ́ ilẹ̀ lórí omi;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

7 Fún ẹni ó àwọn ìmọ́lẹ̀ ńlá;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

8 Òòrùn láti jẹ ọba ̀sán;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

9 Òṣùpá àti ìràwọ̀ láti jẹ ọba òru;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

10 Fún ẹni ó kọlu Ejibiti lára àwọn àkọ́wọn;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

11 Ó Israẹli jáde kúrò láàrín wọn;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

12 Pẹ̀ọwọ́ agbára àti apá nínà;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

13 Fún ẹni ó pín Òkun pupa ìyà;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

14 Ó Israẹli kọjá láàrín rẹ̀

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

15 Ṣùgbọ́n ó bi Farao àti ogun rẹ̀ ṣubú nínú Òkun pupa;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

16 Fún ẹni ó sin àwọn ènìyàn rẹ̀ la aginjù

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

17 Fún ẹni ó kọlu àwọn ọba ńlá;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

18 Ó pa àwọn ọba olókìkí

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

19 Sihoni, ọba àwọn ará Amori

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

20 Àti Ogu, ọba Baṣani;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

21 Ó fi ilẹ̀ wọn fún ni ìní,

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

22 Ìní fún Israẹli, ìránṣẹ́ rẹ̀,

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

23 Ẹni ó rántí wa ìwà ìrẹ̀lẹ̀ wa;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

24 Ó wa ìdè lọ́wọ́ àwọn ̀wa;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

25 Ẹni ó fi oúnjẹ fún àwọn ̀gbogbo

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

26 fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run ̀run;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-