Publicidade

Dar

Por Bíblia Online

Dar é princípio do Reino de Deus. Jesus deu tudo — até a própria vida. A Bíblia nos ensina que é mais bem-aventurado dar do que receber, e que Deus ama ao que dá com alegria.

Dar com alegria

Deus ama ao que dá com alegria. Dai e dar-se-vos-á. O generoso prospera e quem abençoa será abençoado.

olúkúlùkù ènìyàn ṣe gẹ́gẹ́ ó ti pinnu ọkàn rẹ̀; í ṣe àfi ìkùnsínú ṣe, tàbí ti àìgbọdọ̀ ṣe; nítorí Ọlọ́run fẹ́ onínúdídùn ọlọ́rẹ.

Ọlọ́run gbogbo oore-ọ̀fẹ́ máa i fún yín; ̀yin ó ànító ohun gbogbo, nígbà gbogbo, máa pọ̀ i iṣẹ́ rere gbogbo.

Ǹjẹ́ ẹni ń fi irúgbìn fún afúnrúgbìn, àti àkàrà fún oúnjẹ, yóò fi irúgbìn fún un yín, yóò sọ ́ di púpọ̀, yóò èso òdodo yín i.

Bẹ́̀ ni a ó sọ yín di ọlọ́rọ̀ nínú ohun gbogbo, fún ìlawọ́ yín gbogbo ń ṣiṣẹ́ ọpẹ́ Ọlọ́run nípa wa.

Nítorí ìpinnu ṣáájú, ó jásí ìtẹ́wọ́gbà gẹ́gẹ́ ohun ènìyàn , í ṣe gẹ́gẹ́ ohun .

fi fún ni, a ó fi fún yín; òsùwọ̀n dáradára, àkìmọ́lẹ̀, àti àmìpọ̀, àkúnwọ́sílẹ̀, ni a ó wọ́n si àyà yín: nítorí òsùwọ̀n náà ̀yin fi wọ́n, òun ni a ó padà fi wọ́n fún yín."

Princípios de generosidade

Honra ao Senhor com as tuas primícias. Não negues o bem a quem o merece. A alma generosa prosperará.

Fi ọrọ̀ rẹ bọ̀wọ̀ fún Olúwa,

pẹ̀àkọ́so oko rẹ,

ṣe fa ọwọ́ ìre sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ àwọn ṣe tìrẹ,

nígbà ó ìkápá rẹ láti ṣe ohun kan.

Ẹni ń ṣoore yóò máa gbèrú i;

ẹni ó tu ẹlòmíràn lára yóò ìtura.

̀bùn máa ń ṣí ̀fún ẹni ń fún ni lẹ́bùn

a un wọlé ̀dọ̀ àwọn olókìkí.

Ó ń fi ìlara ṣe ojúkòkòrò gbogbo ọjọ́:

ṣùgbọ́n olódodo a máa fi fún ni í í dáwọ́ dúró.

Sọ̀rọ̀ o ṣe ìdájọ́ àìṣègbè

fún ̀tọ́ àwọn tálákà àti aláìní."

gbogbo ìdámẹ́wàá ilé ìṣúra, oúnjẹ à ilé mi, fi èyí dán mi ," Olúwa àwọn ọmọ-ogun , "èmi àwọn fèrèsé ̀run fún yin, èmi ìbùkún àkúnwọ́sílẹ̀ jáde fún yín, bẹ́̀ yóò ààyè láti gbà á.

O ensino de Jesus

Quando deres esmola, não toque a trombeta. A generosidade do coração importa mais que a grandeza do donativo.

"Nítorí náà, nígbà ti ́ ti ń fún aláìní, ṣe fi fèrè kéde rẹ̀, gẹ́gẹ́ àwọn àgàbàgebè ti í ṣe Sinagọgu àti ìta gbangba; àwọn ènìyàn le yìn wọ́n. Lóòótọ́ ni mo fún yín, wọ́n ti gba èrè wọn kíkún.

Ṣùgbọ́n ìwọ ń fi fún aláìní, ṣe jẹ́ ọwọ́ òsì rẹ mọ ohun ọwọ́ ̀tún rẹ ń ṣe, ìfúnni rẹ ṣe jẹ́ mọ̀. Nígbà náà ni Baba rẹ̀, ó mọ ohun ìkọ̀kọ̀ gbogbo, yóò san án fún .

máa ṣe ìwòsàn fún àwọn aláìsàn, si àwọn òkú dìde, sọ àwọn adẹ́tẹ̀ di mímọ́, máa àwọn ̀èṣù jáde. ̀fẹ́ ni ̀yin gbà á, ̀fẹ́ ni fi fún ni.

Jesu fún un , "ìwọ fẹ́ di ẹni pípé, lọ ta ohun gbogbo ìwọ , o fi owó rẹ̀ tọrẹ fún àwọn aláìní. Ìwọ yóò ọrọ̀ ńlá ̀run. Lẹ́yìn náà, láti máa tọ̀ mi lẹ́yìn."

fi fún gbogbo ẹni ó tọrọ lọ́dọ̀ rẹ; lọ́dọ̀ ẹni ó ẹrù, ṣe padà béèrè.

Ṣe inú dídùn Olúwa;

òun yóò fún ìfẹ́ inú rẹ̀.

Àwọn ènìyàn búburú , wọn san án padà,

ṣùgbọ́n àwọn olódodo a máa ṣàánú, a máa fi fún ni;

"Ṣùgbọ́n ta ni èmi, àti ta ni àwọn ènìyàn mi, a fi ṣe ìrànlọ́wọ́ tinútinú irú èyí? Gbogbo nǹkan láti ̀dọ̀ rẹ ti , àwa ti fífún láti ara ohun ó láti ọwọ́ rẹ.

Nehemiah , "lọ gbádùn oúnjẹ yàn láàyò ohun dídùn, díẹ̀ ránṣẹ́ àwọn . Ọjọ́ yìí, mímọ́ ni fún Olúwa wa. ṣe banújẹ́, nítorí ayọ̀ Olúwa ni agbára yín."

mo fi gbogbo nǹkan mo tọrẹ fún àwọn aláìní, mo fi ara mi fún ni láti sùn ṣùgbọ́n n ìfẹ́, èrè kan fún mi.

Seja o primeiro
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_15-35-42-