Publicidade

Provérbios 18

1 Ènìyàn ba ni rẹ́ a máa lépa ìmọ̀ ara rẹ̀;

ó kọjú ìjà gbogbo ìdájọ́ òdodo.

2 Aláìgbọ́n inú dídùn òye

ṣùgbọ́n ó inú dídùn sísọ èrò tirẹ̀.

3 Nígbà ti ènìyàn búburú ni ̀gàn ,

nígbà ti ̀gàn ni ìtìjú .

4 ̀rọ̀ ẹnu ènìyàn jẹ́ omi jíjìn,

ṣùgbọ́n orísun ọgbọ́n jẹ́ odò ń sàn.

5 dára ènìyàn ṣe ojúsàájú fún ènìyàn búburú

tàbí a fi ìdájọ́ òdodo du aláìṣẹ̀.

6 Ètè aláìgbọ́n ìjà sílẹ̀

ẹnu rẹ̀ ń ṣokùnfà ẹgba.

7 Ẹnu aláìgbọ́n ni ó ba tirẹ̀ jẹ́,

ètè rẹ̀ jẹ́ ìdẹ̀kùn fún ọkàn rẹ̀.

8 ̀rọ̀ olófòófó dàbí oúnjẹ àdídùn;

wọ́n a wọ ìsàlẹ̀ inú lọ.

9 Ẹni ṣe déédé nínú iṣẹ́ rẹ̀

arákùnrin jẹ́ fún apanirun.

10 Orúkọ Olúwa, ilé ìṣọ́ agbára ni;

olódodo wọ inú rẹ̀, ó ìgbàlà.

11 ̀rọ̀ olówó ni ìlú olódi wọn;

wọ́n ó i odi ṣe é gùn ni.

12 Ṣáájú ìṣubú ọkàn ènìyàn a kọ́kọ́ máa gbéraga,

ṣùgbọ́n ìrẹ̀lẹ̀ ni ó máa ń ṣáájú ọlá.

13 Ẹni ó ń fèsì ó gbọ́,

èyí ni ìwà òmùgọ̀ àti ìtìjú rẹ̀.

14 Ọkàn ènìyàn a máa gbé e nígbà àìsàn,

ṣùgbọ́n ta ni ó le forí ti ọkàn ó rẹ̀wẹ̀.

15 Ọkàn olóye i gba ìmọ̀;

etí ọlọ́gbọ́n í ṣe àwárí rẹ̀.

16 ̀bùn máa ń ṣí ̀fún ẹni ń fún ni lẹ́bùn

a un wọlé ̀dọ̀ àwọn olókìkí.

17 Ẹni ó kọ́kọ́ rọjọ́ máa ń dàbí i ó jàre,

títí ẹlòmíràn yóò fi bọ́ síwájú ó àṣírí gbogbo.

18 Ìbò dídì máa ń parí ìjà

a àwọn alátakò méjì jìnnà ara wọn.

19 Arákùnrin a ṣẹ̀ ṣòro yípadà ju ìlú olódi lọ,

ìjà wọ dàbí ̀ìdábùú ààfin.

20 Láti inú èso ẹnu rẹ̀ ikùn ènìyàn a ;

láti inú ìkórè ẹnu rẹ̀ ni ó ti jẹ .

21 Ikú àti ìyè ń bẹ nípa ahọ́n wọn,

àwọn ó fẹ́ràn rẹ̀ yóò jẹ ́.

22 Ẹni ó aya fẹ́, ohun rere,

o gba ojúrere lọ́dọ̀ Olúwa.

23 Tálákà ń bẹ̀bẹ̀ fún àánú,

ṣùgbọ́n ọlọ́rọ̀ a dáhùn pẹ̀ìkanra.

24 Ènìyàn ó ̀rẹ́ púpọ̀ le è parun,

ṣùgbọ́n ̀rẹ́ kan ó súnmọ́ ni tímọ́tímọ́ ju arákùnrin.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-