Publicidade

Provérbios 31

1 Àwọn ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ ti Lemueli ọba, ̀rọ̀ ̀kọ́ ìyá rẹ̀ kọ́ ,

2 "Gbọ́ ìwọ ọmọ mi, gbọ́ ìwọ ọmọ inú mi!

Gbọ́ ìwọ ọmọ ̀jẹ́ mi.

3 ṣe lo agbára rẹ lórí obìnrin,

okun rẹ lórí àwọn ó pa àwọn ọba run.

4 "í ṣe fún àwọn ọba, ìwọ Lemueli,

í ṣe fún ọba láti mu ọtí wáìnì,

í ṣe fún alákòóso láti máa ọtí líle,

5 wọn ba à mu ọtí wọn gbàgbé ohun òfin ,

wọn fi ̀tọ́ àwọn ara ń ni wọ́n.

6 Fi ọtí líle fún àwọn ń ṣègbé

wáìnì fún àwọn ó nínú ìrora.

7 Jẹ́ wọn mu ọtí wọn gbàgbé òsì wọn

wọn rántí òsì wọn mọ́.

8 "Sọ̀rọ̀ lórúkọ àwọn le sọ̀rọ̀ fúnra wọn

fún ̀tọ́ àwọn ẹni ń parun.

9 Sọ̀rọ̀ o ṣe ìdájọ́ àìṣègbè

fún ̀tọ́ àwọn tálákà àti aláìní."

10 Ta ni ó le aya oníwà rere?

Ó níye lórí ju iyùn lọ.

11 Ọkọ rẹ̀ ìgbẹ́kẹ̀púpọ̀ nínú rẹ̀

ṣí ìwà rere lọ́wọ́ rẹ̀.

12 Ire ó ń ṣe fún un, í ṣe ibi

gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀.

13 Ó sa aṣọ irun àgùntàn olówùú àti ̀gbọ̀

Ó ṣiṣẹ́ pẹ̀ìyárí.

14 Ó dàbí ọkọ̀ ojú omi àwọn oníṣòwò;

ó ń gbé oúnjẹ rẹ̀ láti ̀jíjìn.

15 Ó dìde nígbà òkùnkùn kùn;

ó ṣe oúnjẹ fún ìdílé rẹ̀

àti ìpín oúnjẹ fún àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀.

16 Ó kíyèsi oko kan, ó á;

nínú ohun ó ń wọlé fún un ó gbin ọgbà àjàrà rẹ̀.

17 Ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ tagbára tagbára

apá rẹ̀ le koko fún iṣẹ́.

18 Ó i òwò òun

fìtílà rẹ̀ í í òru.

19 ọwọ́ rẹ̀, ó di kẹ̀kẹ́ òwú

ó na ọwọ́ rẹ̀ di ìrànwú .

20 O la ọwọ́ rẹ̀ àwọn tálákà

ó na ọwọ́ rẹ̀ àwọn aláìní.

21 Nígbà òjò-dídì rọ̀, bẹ̀nítorí ìdílé rẹ̀

nítorí gbogbo wọn ni ó wọ aṣọ ó nípọn.

22 Ó ṣe aṣọ títẹ́ fún ibùsùn rẹ̀;

̀dáradára àti elése àlùkò ni aṣọ rẹ̀.

23 A bọ̀wọ̀ fún ọkọ rẹ̀ ẹnu ibodè ìlú

níbi ó ń jókòó láàrín àwọn àgbàgbà ìlú.

24 Ó ń ṣe àwọn aṣọ dáradára ó ń wọ́n

ó ń ọjà fún àwọn oníṣòwò.

25 Agbára àti ọlá ni ó ́ láṣọ

ó le fi ọjọ́ iwájú rẹ́rìn-ín.

26 A sọ̀rọ̀ pẹ̀ọgbọ́n

ìkọ́ni òtítọ́ ń bẹ létè e rẹ̀

27 Ó ń bojútó gbogbo ètò ilé rẹ̀

í í jẹ oúnjẹ ìmẹ́lẹ́.

28 Àwọn ọmọ rẹ̀ dìde wọ́n é alábùkún

ọkọ rẹ̀ pẹ̀ń gbóríyìn fún un.

29 "̀pọ̀lọpọ̀ obìnrin ń ṣe nǹkan ọlọ́

ṣùgbọ́n ìwọ ju gbogbo wọn lọ."

30 Ojú dáradára a máa tan ni, ẹwà jẹ́ asán

nítorí obìnrin ó bẹ̀Olúwa yẹ ó gba oríyìn.

31 fún un èrè ó tọ́ i

o jẹ́ iṣẹ́ rẹ̀ fún un ìyìn ẹnu ibodè ìlú.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-