Publicidade

Gratidão a Deus

Por Bíblia Online

A gratidão a Deus é atitude que transforma a vida. Reconhecer que toda boa dádiva vem de Deus nos leva a louvar, servir e viver com alegria e propósito.

Tudo vem de Deus

Toda boa dádiva vem do alto. Agradecer a Deus é reconhecer que Ele é a fonte de toda bênção e sustento.

Nítorí gbogbo ohun ti Ọlọ́run ni ó dára, ọkàn ó yẹ a kọ̀, a fi ọpẹ́ gbà á.

Nítorí gbogbo ohun ti Ọlọ́run ni ó dára, ọkàn ó yẹ a kọ̀, a fi ọpẹ́ gbà á. Nítorí a fi ̀rọ̀ Ọlọ́run àti àdúrà mímọ́.

Oore-ọ̀fẹ́ Olúwa Paulu

Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ ẹni ó fún mi agbára, àní Kristi Jesu Olúwa wa, nítorí ó olóòtítọ́ yíyànmí iṣẹ́ rẹ̀.

Àwọn ̀kọ́ lórí ìsìn

Nítorí náà mo gbà yín níyànjú ṣáájú ohun gbogbo, a máa bẹ̀bẹ̀, a máa gbàdúrà, a máa ṣìpẹ̀, àti a máa dúpẹ́ nítorí gbogbo ènìyàn.

a máa dúpẹ́ nígbà gbogbo lọ́wọ́ Baba, ẹni ó yín láti jẹ́ alábápín nínú ogún àwọn ẹni mímọ́ nínú ìjọba ìmọ́lẹ̀.

fi gbòǹgbò múlẹ̀, a gbé yín nínú rẹ̀, fi ẹsẹ̀ múlẹ̀ nínú ìgbàgbọ́ yín, a ti kọ́ yín, àti máa pọ̀ nínú rẹ̀ pẹ̀ọpẹ́.

jẹ́ àlàáfíà Ọlọ́run ó máa ṣe àkóso ọkàn yín, sínú èyí a yín pẹ̀nínú ara kan; máa dúpẹ́.

Louvor e gratidão

Louvai ao Senhor e dai-lhe graças! Ele fez maravilhas e é digno de todo louvor e agradecimento.

Èmi ó fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí òdodo rẹ̀,

èmi ó kọrin ìyìn Olúwa ̀gá-ògo jùlọ.

"ẹbọ ọpẹ́ Ọlọ́run,

o san ̀jẹ́ rẹ fún ̀gá-ògo.

Èmi yóò fi orin gbé orúkọ Ọlọ́run ga

èmi yóò fi ọpẹ́ gbé orúkọ rẹ̀ ga.

Ṣùgbọ́n àwọn ó ń ó máa yọ̀

inú wọn ó máa dùn nípa rẹ,

àwọn ó ń fẹ́ ìgbàlà rẹ máa ,

"Jẹ́ a gbé Ọlọ́run ga!"

Fún adarí orin. ohùn, "ṣe parun." Saamu ti Asafu. Orin.

A fi ìyìn fún , Ọlọ́run,

a yìn ́, nítorí orúkọ rẹ súnmọ́ tòsí;

àwọn ènìyàn ń sọ ti ìyanu rẹ.

Nígbà náà àwa ènìyàn rẹ,

àti àgùntàn pápá rẹ,

yóò fi ọpẹ́ fún títí láé;

láti ìran ìran

ni àwa ó fi ìyìn rẹ hàn.

lọ ẹnu-ọ̀rẹ̀ pẹ̀ọpẹ́

àti àgbàlá rẹ̀ pẹ̀ìyìn;

fi ọpẹ́ àti ìyìn fún orúkọ rẹ̀.

Ìwọ ti ìkáàánú mi di ijó fún mi;

ìwọ ti bọ́ aṣọ ̀fọ̀ mi, o fi aṣọ ayọ̀ wọ̀ ,

nítorí ìdí èyí ni ọkàn mi máa yìn ́, o ṣe dákẹ́.

Ìwọ Olúwa Ọlọ́run mi, èmi yóò máa fi ọpẹ́ fún títí láé.

fi ọpẹ́ fún Olúwa, pe orúkọ rẹ̀,

fi iṣẹ́ rẹ̀ hàn nínú àwọn ènìyàn fún ohun ó ṣe

Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí ó dára;

ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láé.

Expressões de gratidão

Dar graças com oração e súplica. A gratidão se expressa em palavras, atos e atitudes que glorificam a Deus.

ṣe ṣe àníyàn ohunkóhun; ṣùgbọ́n nínú ohun gbogbo, nípa àdúrà àti ̀bẹ̀ pẹ̀ìdúpẹ́, máa fi ìbéèrè yín hàn fún Ọlọ́run.

máa dúpẹ́ nígbà gbogbo fún ohun gbogbo lọ́wọ́ Ọlọ́run, àní Baba, orúkọ Jesu Kristi Olúwa .

Ìbá à ṣe ìwà ̀bùn, àti ìṣọ̀rọ̀ òmùgọ̀, tàbí ìṣẹ̀fẹ̀ àwọn ohun tọ́; ṣùgbọ́n kúkú máa dúpẹ́.

Bẹ́̀ ni a ó sọ yín di ọlọ́rọ̀ nínú ohun gbogbo, fún ìlawọ́ yín gbogbo ń ṣiṣẹ́ ọpẹ́ Ọlọ́run nípa wa.

Nítorí tiyín gbogbo rẹ̀, ki ̀pẹ púpọ̀ fún ògo Ọlọ́run gẹ́gẹ́ oore-ọ̀fẹ́ ti ń gbòòrò i fún ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn.

máa dúpẹ́ nígbà gbogbo nínú ipòkípò o ; nítorí , èyí ni ìfẹ́ Ọlọ́run fún yin nínú Kristi Jesu nítòótọ́.

:

"Àwa fi ọpẹ́ fún , Olúwa Ọlọ́run, Olódùmarè,

ń bẹ, ó ti ,

nítorí ìwọ ti gba agbára ńlá rẹ̀,

ìwọ ti jẹ ọba.

Ṣùgbọ́n èmi yóò fi orin ọpẹ́, ẹbọ .

Èmi yóò san ̀jẹ́ mo ti jẹ́.

Ìgbàlà láti ̀dọ̀ Olúwa.’ "

Seja o primeiro
Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-