Publicidade

Salmos 30

Saamu. Orin. Fún ìyàsímímọ́ Tẹmpili. Ti Dafidi.

1 Èmi yóò kókìkí i rẹ, Olúwa,

nítorí ìwọ ni ó gbé mi lékè

ìwọ jẹ́ àwọn ̀mi ó yọ̀ .

2 Olúwa Ọlọ́run mi, èmi ́ fún ìrànlọ́wọ́,

ìwọ ti sàn.

3 Olúwa, ìwọ ti yọ ọkàn mi jáde kúrò nínú isà òkú,

mi padà bọ̀ sípò alààyè èmi ba à lọ sínú ihò.

4 Kọ orin ìyìn Olúwa, ̀yin olódodo;

fi ọpẹ́ fún orúkọ rẹ̀ mímọ́.

5 Nítorí ìbínú rẹ̀ fún ìgbà díẹ̀,

ojúrere rẹ̀ títí ayérayé;

ẹkún pẹ́ títí di alẹ́,

ṣùgbọ́n ayọ̀ yóò òwúrọ̀.

6 ìgbà ayé mi, mo ,

"a yóò ṣí mi ipò padà."

7 Nípa ojúrere rẹ, Olúwa,

ìwọ ti gbé mi kalẹ̀ òkè ó agbára;

ìwọ pa ojú rẹ mọ́,

àyà .

8 Olúwa, ni mo é;

àti Olúwa ni mo sọkún fún àánú:

9 "Èrè ni ó nínú ikú ìparun mi,

nínú lílọ ihò mi?

Eruku yóò a yìn ́ ?

Ǹjẹ́ yóò sọ nípa òdodo rẹ?

10 Gbọ́, Olúwa, o ṣàánú fún mi;

ìwọ Olúwa, jẹ́ olùrànlọ́wọ́ mi."

11 Ìwọ ti ìkáàánú mi di ijó fún mi;

ìwọ ti bọ́ aṣọ ̀fọ̀ mi, o fi aṣọ ayọ̀ wọ̀ ,

12 nítorí ìdí èyí ni ọkàn mi máa yìn ́, o ṣe dákẹ́.

Ìwọ Olúwa Ọlọ́run mi, èmi yóò máa fi ọpẹ́ fún títí láé.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-