Publicidade

1 Crônicas 16

Orin ọpẹ́ Dafidi

1 Wọ́n gbé àpótí ̀Ọlọ́run, sínú àgọ́ ti Dafidi ti pèsè fún un, wọ́n gbé ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀ kalẹ̀ níwájú Ọlọ́run. 2 Lẹ́yìn Dafidi parí ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀, ó bùkún àwọn ènìyàn orúkọ Olúwa. 3 Nígbà náà ó fún olúkúlùkù ọkùnrin àti obìnrin ọmọ Israẹli ìṣù àkàrà kan, àkàrà dídùn ti àkókò kan àti àkàrà dídùn ti èso àjàrà kan.

4 Ó yan díẹ̀ lára àwọn ará Lefi láti máa jọ́sìn níwájú àpótí ̀Olúwa, àti láti ṣe ìrántí àti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli. 5 Asafu ni olóyè, àtẹ̀rẹ ni Sekariah, Jehieli, Ṣemiramotu, Asieli, Mattitiah, Eliabu, Benaiah, Obedi-Edomu àti Jeieli, àwọn ni yóò lu ohun èlò orin olókùn àti dùùrù haapu. Asafu ni yóò lu símbálì kíkan. 6 Àti Benaiah àti Jahasieli àwọn àlùfáà ni yóò fọn ìpè nígbà gbogbo níwájú àpótí ̀májẹ̀ti Ọlọ́run.

7 ọjọ́ náà Dafidi kọ́kọ́ fi Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ orin Dafidi ti ọpẹ́ Olúwa.

8 fi ọpẹ́ fún Olúwa, pe orúkọ rẹ̀,

fi iṣẹ́ rẹ̀ hàn nínú àwọn ènìyàn fún ohun ó ṣe

9 kọrin i, kọrin ìyìn, i,

sọ ti gbogbo iṣẹ́ ìyanu rẹ̀.

10 Ìyìn nínú orúkọ rẹ̀ mímọ́;

jẹ ọkàn àwọn ó yin Olúwa ó yọ̀.

11 Olúwa àti agbára rẹ̀;

e ojú rẹ̀ nígbà gbogbo.

12 Rántí àwọn ìyanu Ó ti ṣe,

iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ àti ìdájọ́ Ó ti sọ.

13 A! ̀yin ìran ọmọ Israẹli ìránṣẹ́ rẹ̀,

àwọn ọmọ Jakọbu, ̀yin ó ti yàn.

14 Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa;

ìdájọ́ rẹ̀ gbogbo ayé.

15 Ó rántí májẹ̀rẹ̀ láéláé,

̀rọ̀ ó pàṣẹ, fún ẹgbẹẹgbẹ̀rún ìran,

16 májẹ̀ó pẹ̀Abrahamu,

ìbúra ó ṣe pẹ̀fún Isaaki.

17 Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu,

gẹ́gẹ́ àṣẹ Israẹli, gẹ́gẹ́ bi májẹ̀ayérayé:

18 ", ni èmi yóò fún ilẹ̀ Kenaani.

Gẹ́gẹ́ ààyè ìwọ yóò jogún."

19 Nígbà wọn kéré iye,

wọ́n kéré gidigidi, wọ́n jẹ́ àlejò níbẹ̀,

20 wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè orílẹ̀-èdè

láti ìjọba kan èkejì.

21 gba ọkùnrin kankan láyè láti pọ́n wọn lójú;

nítorí tiwọn, ó àwọn ọba .

22 "ṣe fọwọ́ kan àwọn ẹni àmì òróró mi;

ṣe pa àwọn wòlíì mi lára."

23 Kọrin Olúwa gbogbo ayé;

máa fi ìgbàlà rẹ̀ hàn láti ọjọ́ ọjọ́.

24 Kéde ògo à rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,

ohun ìyàlẹ́nu ó ṣe láàrín gbogbo ènìyàn.

25 Nítorí títóbi ni Olúwa òun ni ìyìn yẹ jùlọ;

òun ni a bẹ̀ju gbogbo àwọn Ọlọ́run lọ.

26 Nítorí gbogbo àwọn ọlọ́run orílẹ̀-èdè jẹ́ àwọn òrìṣà,

ṣùgbọ́n Olúwa àwọn ̀run.

27 Dídán àti ọláńlá ni ó níwájú rẹ̀;

agbára àti ayọ̀ ni ó ibi ibùgbé rẹ̀.

28 Fi fún Olúwa, ̀yin ìdílé àwọn orílẹ̀-èdè,

fi ògo àti ipá fún Olúwa.

29 Fún Olúwa ìyìn nítorí orúkọ rẹ̀;

gbé ọrẹ síwájú rẹ̀.

Sìn Olúwa nínú inú dídùn ìwà mímọ́ rẹ̀.

30 Wárìrì níwájú rẹ̀, gbogbo ayé!

Ayé fi ìdí múlẹ̀; a le è ṣí i.

31 Jẹ́ àwọn ̀run ó yọ̀, jẹ́ ayé ó ṣe inú dídùn;

lẹ́ wọn ó sọ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, "Olúwa jẹ ọba!"

32 Jẹ́ ̀run ó tún dún padà, àti gbogbo ohun ó nínú rẹ̀;

Jẹ́ àwọn pápá ó fún ayọ̀, àti gbogbo ohun ó nínú rẹ̀!

33 Nígbà náà ni igi igbó yóò kọrin,

wọn yóò kọrin fún ayọ̀ níwájú Olúwa,

nítorí ó láti ṣèdájọ́ ayé.

34 Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí ó dára;

ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láé.

35 lóhùn rara, "Gbà , Ọlọ́run olùgbàlà a wa;

wa jọ o gbà kúrò lọ́wọ́ àwọn orílẹ̀-èdè,

àwa ó fi ọpẹ́ fún orúkọ mímọ́ rẹ,

àwa ó yọ̀ nínú ìyìn rẹ̀."

36 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,

láé àti láéláé.

Lẹ́yìn náà gbogbo àwọn ènìyàn , "Àmín," wọ́n "Yin Olúwa."

37 Dafidi fi Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ níwájú àpótí ̀Olúwa láti jíṣẹ́ níbẹ̀ déédé, gẹ́gẹ́ ọjọ́ kọ̀̀kan ṣe gbà. 38 Ó fi Obedi-Edomu àti méjìdínláàádọ́rin ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ láti ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀wọn. Obedi-Edomu mọ Jedutuni, àti Hosa pẹ̀jẹ́ olùtọ́ẹnu-ọ̀.

39 Dafidi fi Sadoku àlùfáà àti àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ níwájú Àgọ́ Olúwa ibi gíga Gibeoni. 40 Láti gbé pẹpẹ ẹbọ sísun déédé, àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ ìbámu pẹ̀gbogbo ohun a kọ sínú òfin Olúwa, ó ti fún Israẹli. 41 Pẹ̀wọn ni Hemani àti Jedutuni àti ìyókù a àti yàn nípasẹ̀ orúkọ láti fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láéláé 42 Hemani àti Jedutuni ni wọ́n dúró fún fífọn ìpè àti Kimbali àti fún lílo ohun èlò yòókù fún orin Ọlọ́run. Àwọn ọmọ Jedutuni ipò dídúró ẹnu-ọ̀.

43 Nígbà náà gbogbo àwọn ènìyàn kúrò, olúkúlùkù ilé rẹ̀: Dafidi yípadà láti súre fún ìdílé rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-