Publicidade

Morte de Jesus

Por Bíblia Online

A morte de Jesus é o sacrifício supremo do amor de Deus. Na cruz, o Cordeiro de Deus carregou os pecados do mundo, satisfez a justiça divina e abriu o caminho da salvação para todos.

O sacrifício na cruz

Jesus disse: 'Está consumado!' Na cruz, Ele cumpriu toda a lei, pagou o preço do pecado e reconciliou a humanidade com Deus.

Ikú Jesu

Lẹ́yìn èyí, Jesu ti mọ̀ , a ti parí ohun gbogbo tán, ìwé mímọ́ á ṣẹ, ó , "Òrùngbẹ ń gbẹ ." Ohun èlò kan ó kún fún ọtí kíkan níbẹ̀, wọ́n tẹ kànìnkànìn ó kún fún ọtí kíkan bọ inú rẹ̀, wọ́n fi orí igi hísópù, wọ́n án i lẹ́nu. Nígbà Jesu ti gba ọtí kíkan náà, ó , "Ó parí!" Ó tẹ orí rẹ̀ ba, ó jọ̀wọ́ ̀rẹ̀.

Nígbà náà ni àwọn ọmọ-ogun, nígbà wọ́n kan Jesu mọ́ àgbélébùú tán, wọ́n aṣọ rẹ̀, wọ́n pín wọn ipa mẹ́rin, apá kan fún ọmọ-ogun kọ̀̀kan, àti ̀àwọ̀tẹ́lẹ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ̀àwọ̀tẹ́lẹ̀ náà ojúràn-án, wọ́n hun ún láti òkè títí jálẹ̀.

Nítorí náà wọ́n fún ara wọn , "jẹ́ a á ya, ṣùgbọ́n a ṣẹ́ gègé nítorí rẹ̀."

Ti ẹni yóò jẹ́: ìwé mímọ́ ó le ṣẹ, ó ,

"Wọ́n pín aṣọ mi láàrín ara wọn,

wọ́n ṣẹ́ gègé fún aṣọ ìlekè mi."

Nǹkan wọ̀nyí ni àwọn ọmọ-ogun ṣe.

Ìyá Jesu àti arábìnrin ìyá rẹ̀ Maria aya Kilopa, àti Maria Magdalene dúró níbi àgbélébùú, nígbà Jesu ìyá rẹ̀ àti ọmọ-ẹ̀yìn náà dúró, ẹni Jesu fẹ́ràn, ó fún ìyá rẹ̀ , "Obìnrin, wo ọmọ rẹ!" Lẹ́yìn náà ni ó fún ọmọ-ẹ̀yìn náà , "Wo ìyá rẹ!" Láti wákàtí náà lọ ni ọmọ-ẹ̀yìn náà ti un lọ ilé ara rẹ̀.

Nígbà wọ́n ibi a ń Agbárí, níbẹ̀ ni wọ́n gbé kàn án mọ́ àgbélébùú, àti àwọn arúfin náà, ̀kan ọwọ́ ̀tún, àti ̀kan ọwọ́ òsì. Jesu , "Baba, dáríjì wọ́n; nítorí wọn mọ ohun wọ́n ń ṣe." Wọ́n di ìbò láti pín aṣọ rẹ̀ láàrín ara wọn.

Àwọn ènìyàn dúró láti wòran. Àti àwọn ìjòyè pẹ̀wọn, wọ́n ń yọ ṣùtì i, , "Ó gba àwọn ẹlòmíràn ; ó gbara rẹ̀ , ó ṣe Kristi, àyànfẹ́ Ọlọ́run."

Àti àwọn ọmọ-ogun pẹ̀ń fi í ṣe ẹlẹ́, wọ́n tọ̀ ́ , wọ́n ń fi ọtí kíkan fún un. Wọ́n ń , "ìwọ ṣe ọba àwọn Júù, gba ara rẹ ."

Wọ́n kọ̀àkọlé ìgbèrí rẹ̀ èdè Giriki, àti ti Latin, àti Heberu pe:

Èyí ni Ọba àwọn Júù.

Àti ̀kan nínú àwọn arúfin a gbé kọ́ ń fi ṣe ẹlẹ́, "ìwọ ṣe Kristi, gba ara rẹ àti àwa náà ."

Ṣùgbọ́n èyí èkejì dáhùn, ó ń a , "Ìwọ bẹ̀Ọlọ́run, ìwọ nínú ̀bi kan náà? tiwa, wọ́n jàre nítorí èrè ohun àwa ṣe ni à ń jẹ, ṣùgbọ́n ọkùnrin yìí ṣe ohun búburú kan."

Ó , "Jesu, rántí mi nígbà ìwọ ìjọba rẹ."

Jesu fún un , "Lóòótọ́ ni mo fún , lónìí ni ìwọ ó pẹ̀mi Paradise!"

Ikú Jesu

Nígbà ó di wákàtí kẹfà, òkùnkùn bo gbogbo ilẹ̀ títí di wákàtí kẹsànán. wákàtí kẹsànán ni Jesu kígbe sókè ohùn rara, ó , "Eli, Eli, lama sabakitani?" (ìtumọ̀ èyí í ṣe, "Ọlọ́run mi, Ọlọ́run mi, èéṣe ìwọ fi kọ̀ sílẹ̀?").

Lójúkan náà aṣọ ìkélé tẹmpili fàya, láti òkè ìsàlẹ̀. Ilẹ̀ tìtì. Àwọn àpáta sán. Àwọn isà òkú ṣí sílẹ̀. ̀pọ̀ òkú àwọn ẹni mímọ́ ó ti sùn tún jíǹde. Wọ́n jáde láti isà òkú lẹ́yìn àjíǹde Jesu, wọ́n lọ ìlú mímọ́. Níbẹ̀ ni wọ́n ti fi ara han ̀pọ̀ ènìyàn.

Nígbà balógun ̀run àti àwọn ó pẹ̀rẹ̀ wọ́n ń sọ Jesu ilẹ̀ ṣe tìtì àti ohun ó ṣẹlẹ̀, ̀wọn gidigidi, wọ́n , "Lóòótọ́ Ọmọ Ọlọ́run í ṣe!"

Ṣùgbọ́n a a lọ́gbẹ́ nítorí àìṣedéédéé wa

a pa á lára nítorí àìṣòdodo wa;

ìjìyà ó àlàáfíà fún wa lórí i rẹ̀,

àti nípa ọgbẹ́ rẹ̀ ni a fi wa láradá.

Gbogbo wa àgùntàn, ti ṣìnà lọ,

ẹnìkọ̀̀kan wa ti ̀ara rẹ̀;

Olúwa ti gbé e ka orí ara rẹ̀

gbogbo àìṣedéédéé wa.

A jẹ ́ , a pọ́n ọn lójú,

síbẹ̀ ya ẹnu rẹ̀;

a un gẹ́gẹ́ ̀dọ́-àgùntàn sọ́dọ̀ alápatà,

àti gẹ́gẹ́ àgùntàn ó dákẹ́ níwájú olùrẹ́run rẹ̀,

síbẹ̀ ya ẹnu rẹ̀.

Àwọn ajá mi ;

ìjọ àwọn ènìyàn ibi ti mi mọ́,

wọ́n gún mi lọ́wọ́, wọ́n gún mi lẹ́sẹ̀.

Mo ka gbogbo àwọn egungun mi;

àwọn tìkára wọn ń , wọ́n dójú mi.

Wọ́n pín aṣọ mi láàrín ara wọn

àní lórí aṣọ mi ni wọ́n ṣẹ́ gègé.

Gbogbo àwọn ó fi ṣe ẹlẹ́;

wọ́n yọ ètè ̀gàn wọn mi, wọ́n ń mi orí wọn .

"Ó gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ Olúwa;

jẹ́ Olúwa gbà á .

Jẹ́ ó gbà á ,

nítorí , ó ayọ̀ nínú rẹ̀."

O amor que se entrega

Ninguém tem maior amor do que aquele que dá a vida pelos amigos. Deus prova seu amor em que Cristo morreu por nós quando ainda éramos pecadores.

ẹnìkan ó ìfẹ́ ó tóbi ju èyí lọ, ẹnìkan fi ̀rẹ̀ lélẹ̀ nítorí àwọn ̀rẹ́ rẹ̀.

"Nítorí Ọlọ́run fẹ́ aráyé bẹ́̀ gẹ́́, ó fi ọmọ rẹ̀ kan ṣoṣo fún ni, ẹnikẹ́ni ó gbà á gbọ́, á ṣègbé, ṣùgbọ́n ó ìyè àìnípẹ̀kun.

Ǹjẹ́, nígbà àwa ̀, a wa, ba Ọlọ́run làjà nípa ikú Ọmọ rẹ̀, mélòó mélòó, nígbà a ìjà tan, ni a ó gbà nípa ìyè rẹ̀.

Nípa èyí ni àwa mọ ìfẹ́ nítorí ó fi ̀rẹ̀ lélẹ̀ fún wa, ó yẹ àwa fi ̀wa lélẹ̀ fún àwọn ará.

Òun ètùtù fún ̀ṣẹ̀ wa, í tilẹ̀ ṣe fún tiwa nìkan ṣùgbọ́n fún ̀ṣẹ̀ gbogbo aráyé.

Ó àwòrán ènìyàn,

ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀,

o tẹríba títí de ojú ikú,

àní ikú lórí àgbélébùú.

Morte e ressurreição

Jesus morreu e ressuscitou, e a morte não mais tem domínio sobre Ele. Pelo batismo, participamos de sua morte e ressurreição.

Nítorí àwa mọ̀ Kristi ti dìde kúrò nínú òkú. Òun mọ́. Ikú agbára lórí rẹ̀ mọ́. Kristi lẹ́̀kan ṣoṣo, láti ṣẹ́gun agbára ̀ṣẹ̀, ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ó láààyè títí ayé àìnípẹ̀kun ìdàpọ̀ mímọ́ pẹ̀Ọlọ́run.

Tàbí ẹyin mọ gbogbo wa ti a ti bamitiisi wa sínú Jesu Kristi ni a ti bamitiisi sínú ikú rẹ. Nítorí náà, a sin wa pẹ̀Kristi nípa ìtẹ̀bọmi si ikú, ó le jẹ́ pe a ti Kristi dìde pẹ̀ògo Baba, àwa pẹ̀gbé ìgbé ayé tuntun.

Níwọ́n a ti fi lélẹ̀ fún gbogbo ènìyàn láti lẹ́̀kan ṣoṣo, ṣùgbọ́n lẹ́yìn èyí ìdájọ́, bẹ́̀ ni Kristi pẹ̀lẹ́yìn a ti fi ẹbọ lẹ́̀kan ṣoṣo láti ru ̀ṣẹ̀ ̀pọ̀lọpọ̀, yóò farahàn ìgbà kejì láìsí ̀ṣẹ̀ fún àwọn n wo ̀rẹ̀ fún ìgbàlà.

"̀yin ènìyàn Israẹli, gbọ́ ̀rọ̀ wọ̀nyí; Jesu Nasareti, ọkùnrin a mọ̀ láti ̀dọ̀ Ọlọ́run nípa iṣẹ́ agbára àti ìyanu, àti àmì ti Ọlọ́run ti ọwọ́ rẹ̀ ṣe láàrín yín, ̀yin tìkára yín ti mọ̀ pẹ̀. Ẹni a ti fi yín lọ́wọ́ nípa ìpinnu ìmọ̀ àti ìmọ̀tẹ́lẹ̀ Ọlọ́run; àti ̀yin pẹ̀, a pa á pẹ̀ìrànlọ́wọ́ àwọn ènìyàn búburú, a kàn mọ́ àgbélébùú. Ṣùgbọ́n Ọlọ́run dìde kúrò nínú òkú, gbà á kúrò nínú ìrora ikú, nítorí ṣe é ṣe fún ikú láti dìímú.

"Èmi ni olùṣọ́-àgùntàn rere, olùṣọ́-àgùntàn rere fi ọkàn rẹ̀ lélẹ̀ nítorí àwọn àgùntàn.

Nítorí nígbàkígbà ń jẹ lára àkàrà yìí, ǹ mu nínú ago yìí, ni tún sọ nípa ikú Olúwa. máa ṣe eléyìí títí yóò fi padà .

Seja o primeiro
Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-