Publicidade

Isaías 53

1 Ta ni ó ti gba ìròyìn in wa gbọ́

àti ta ni a ti fi apá Olúwa hàn fún?

2 Òun dàgbàsókè níwájú rẹ̀ gẹ́gẹ́ àṣẹ̀ṣẹ̀yọ irúgbìn,

àti gẹ́gẹ́ i gbòǹgbò ó jáde láti inú ìyàngbẹ ilẹ̀.

Òun ẹwà tàbí ògo láti sọ́dọ̀ ara rẹ̀,

ohun kankan nínú àbùdá rẹ̀

ó fi yẹ a ṣàfẹ́i rẹ̀.

3 A kẹ́gàn rẹ̀ àwọn ènìyàn kọ̀ ́ sílẹ̀,

ẹni ìbànújẹ́, ó mọ ìpọ́njú ti .

Gẹ́gẹ́ ẹnìkan àwọn ènìyàn ń fojú pamọ́ fún

a kẹ́gàn rẹ, a bu ọlá fún un rárá.

4 Lóòtítọ́ ó ti ru àìlera wa lọ

ó ti ru ìbànújẹ́ wa pẹ̀,

síbẹ̀ a á ẹni Ọlọ́run ,

ó , a pọ́n lójú.

5 Ṣùgbọ́n a a lọ́gbẹ́ nítorí àìṣedéédéé wa

a pa á lára nítorí àìṣòdodo wa;

ìjìyà ó àlàáfíà fún wa lórí i rẹ̀,

àti nípa ọgbẹ́ rẹ̀ ni a fi wa láradá.

6 Gbogbo wa àgùntàn, ti ṣìnà lọ,

ẹnìkọ̀̀kan wa ti ̀ara rẹ̀;

Olúwa ti gbé e ka orí ara rẹ̀

gbogbo àìṣedéédéé wa.

7 A jẹ ́ , a pọ́n ọn lójú,

síbẹ̀ ya ẹnu rẹ̀;

a un gẹ́gẹ́ ̀dọ́-àgùntàn sọ́dọ̀ alápatà,

àti gẹ́gẹ́ àgùntàn ó dákẹ́ níwájú olùrẹ́run rẹ̀,

síbẹ̀ ya ẹnu rẹ̀.

8 Pẹ̀ìpọ́nlójú àti ìdánilẹ́jọ́ ni a un jáde lọ,

ta ni ó le sọ nípa ìrànlọ́wọ́ rẹ̀?

Nítorí a e kúrò ilẹ̀ àwọn alààyè;

nítorí àìṣedéédéé àwọn ènìyàn mi ni a ṣe ú.

9 A fún un ibojì pẹ̀àwọn ìkà,

àti pẹ̀àwọn ọlọ́rọ̀ ikú rẹ̀,

ó tilẹ̀ jẹ́ hùwà jàgídíjàgan kan,

tàbí a ̀tàn kan ẹnu rẹ̀.

10 Síbẹ̀, ó wu Olúwa láti pa á lára

àti láti ó jìyà,

ó tilẹ̀ jẹ́ Olúwa fi ayé rẹ̀

fún ẹbọ ̀ṣẹ̀,

Òun yóò àrọ́mọdọ́mọ rẹ̀ àti ọjọ́ ayé

rẹ̀ yóò pẹ́ títí,

àti ète Olúwa ni yóò gbèrú ọwọ́ rẹ̀.

11 Lẹ́yìn ìpọ́njú ̀rẹ̀,

òun yóò ìmọ́lẹ̀, ààyè yóò tẹ́ lọ́rùn;

nípa ìmọ̀ rẹ̀ ìránṣẹ́ mi olódodo yóò ̀pọ̀lọpọ̀ láre,

Òun ni yóò ru àìṣedéédéé wọn.

12 Nítorí náà èmi yóò fún un ìpín pẹ̀àwọn ẹni ńlá

òun yóò pín ìkógun pẹ̀àwọn alágbára,

nítorí òun jọ̀wọ́ ̀rẹ̀ fún ikú,

a á mọ́ àwọn alárékọjá.

Nítorí ó ru ̀ṣẹ̀ ̀pọ̀lọpọ̀,

ó ṣe ìlàjà fún àwọn alárékọjá.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-